< Isaiah 15 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Moabu, a pa Ari run ní Moabu, òru kan ní a pa á run! A pa Kiri run ní Moabu, òru kan ní a pa á run!
Břímě Moábských. Když v noci Ar Moábské popléněno a zkaženo bude, když i Kir Moábské v noci popléněno a zkaženo bude,
2 Diboni gòkè lọ sí tẹmpili rẹ̀, sí àwọn ibi gíga rẹ̀ láti sọkún, Moabu pohùnréré lórí Nebo àti Medeba. Gbogbo orí ni a fá gbogbo irùngbọ̀n ni a gé dànù.
Vstoupí do Baít, a do Dibon a do Bamot s pláčem, nad Nébo a nad Medaba Moáb kvíliti bude, na všech hlavách jeho bude lysina, a každá brada oholena bude.
3 Wọ́n wọ aṣọ ọ̀fọ̀ ní ojú òpópónà, ní àwọn òrùlé àti àwọn gbàgede ìlú. Wọ́n pohùnréré, wọ́n dọ̀bálẹ̀ pẹ̀lú ẹkún.
Na ulicích jeho přepáší se žíní, na střechách jeho i na ryncích jeho každý kvíliti bude, s pláčem se vraceje.
4 Heṣboni àti Eleale ké sóde, ohùn wọn ni a gbọ́ títí fi dé Jahasi. Nítorí náà ni àwọn ọmọ-ogun Moabu ṣe kígbe tí ọkàn wọn sì rẹ̀wẹ̀sì.
A křičeti bude Ezebon a Eleale, až v Jasa slyšán bude hlas jejich, nýbrž i zbrojní Moábští křičeti budou. Duše každého z nich žalostiti bude, a řekne:
5 Ọkàn mi kígbe sókè lórí Moabu; àwọn ìsáǹsá rẹ sálà títí dé Soari, títí fi dé Eglati-Ṣeliṣi. Wọ́n gòkè lọ títí dé Luhiti wọ́n ń sọkún bí wọ́n ti ń lọ, ní òpópónà tí ó lọ sí Horonaimu wọ́n ń pohùnréré ìparun wọn.
Srdce mé řve nad Moábem a pevnostmi jeho, až slyšeti v Ségor, jako jalovice tříletá; nebo cestou Luchitskou s pláčem půjde, a kudyž se chodí k Choronaim, křik hrozný vydávati budou,
6 Gbogbo omi Nimrimu ni ó ti gbẹ àwọn koríko sì ti gbẹ, gbogbo ewéko ti tán ewé tútù kankan kò sí mọ́.
Proto že vody Nimrim vymizejí, že uschne bylina, usvadne tráva, aniž co zeleného bude.
7 Báyìí gbogbo ọrọ̀ tí wọ́n ti ní tí wọ́n sì tò jọ wọ́n ti kó wọn kọjá lọ lórí i gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ odò Poplari.
A protož zboží nachované a statky jejich odnesou ku potoku Arabim.
8 Gbohùngbohùn ń gba igbe wọn dé ìpẹ̀kun ilẹ̀ Moabu; ìpohùnréré wọn lọ títí dé Eglaimu, igbe ẹkún wọn ni a gbọ́ títí dé kànga Elimu.
Nebo křik obejde vůkol meze Moábské, až do Eglaim kvílení jeho, a až do Beer Elim kvílení jeho,
9 Omi Dimoni kún fún ẹ̀jẹ̀, síbẹ̀ èmi ó tún mu ohun tí ó jù báyìí lọ wá sórí Dimoni— kìnnìún kan wá sórí àwọn ìsáǹsá Moabu àti lórí àwọn tí ó tún ṣẹ́kù sórí ilẹ̀ náà.
Poněvadž i vody Dimon naplněny budou krví. Přidám zajisté Dimonu přídavků, a pošli na ty, kteříž ujdou z Moábských, lvy, i na pozůstalé v té zemi.

< Isaiah 15 >