< Isaiah 13 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Babeli èyí tí Isaiah ọmọ Amosi rí.
KA wanana no Babulona, ka mea a Isaia, ke keiki a Amosa i ike ai.
2 Gbé àsíá sókè ní orí òkè gbẹrẹfu, kígbe sí wọn, pè wọ́n láti wọlé sí ẹnu-ọ̀nà àwọn ọlọ́lá.
E kau i ka hae ma ka mauna olohelohe, E hookiekie i ka leo io lakou la, e peahi ka lima, I komo lakou maloko o na pukapa o na'lii.
3 Mo ti pàṣẹ fún àwọn ẹni mímọ́ mi, mo ti pe àwọn jagunjagun mi láti gbé ìbínú mi jáde àwọn tí ń yọ̀ nínú ìṣẹ́gun mi.
Ua kauoha aku au i ko'u poe i hookaawaleia no ke kaua, A no ka ukiuki, ua hea aku au i ko'u poe koa, Kuu poe olioli me ka hookiekie.
4 Gbọ́ ohùn kan ní àwọn orí òkè, gẹ́gẹ́ bí i ti ogunlọ́gọ̀ ènìyàn. Gbọ́ ìdàrúdàpọ̀ láàrín àwọn ìjọba, gẹ́gẹ́ bí i ti ìkórajọ àwọn orílẹ̀-èdè! Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti kó ogun rẹ̀ jọ àwọn jagunjagun fún ogun.
Ka hooho ka a ka poe nui muluna o na mauna, E like me ko ka lahuikanaka nui; Ka hooho o ka hui ana o na aupuni, A me na aina i hoakoakoaia. O Iehova o na kaua, e hoolalelale ana ia i ke kaua no ka hoouka.
5 Wọ́n wá láti ọ̀nà jíjìn réré, láti ìpẹ̀kun ọ̀run wá Olúwa pẹ̀lú àwọn ohun ìjà ìbínú rẹ̀, láti pa gbogbo orílẹ̀-èdè náà run.
Hele mai no lakou, mai ka aina mamao aku, A mai ka welau mai o ka lani; O Iehova, a me na mea hoopai o kona ukiuki, E anai i ka aina a pau.
6 Ẹ hu, nítorí ọjọ́ Olúwa súnmọ́ tòsí, yóò sì wá gẹ́gẹ́ bí ìparun láti ọ̀dọ̀ Alágbára jùlọ.
E aoa oukou, no ka mea, ua kokoke mai ka la o Iehova; E hiki mai no ia, e like me ka puahiohio, mai ka Mea Mana mai.
7 Nítorí èyí, gbogbo ọwọ́ ni yóò rọ, ọkàn ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò rẹ̀wẹ̀sì.
Nolaila, e lewa wale ilalo na lima a pau, A e maule hoi na naau a pau o kanaka:
8 Ẹ̀rù yóò gbá wọn mú, ìrora àti ìpayínkeke yóò dìwọ́n mú, wọn yóò kérora gẹ́gẹ́ bí obìnrin tí ó ń rọbí. Ẹnìkínní yóò wo ẹnìkejì rẹ̀ pẹ̀lú ìpayà ojú wọn á sì gbinájẹ.
E makau ananet lakou; E loohia lakou i ka eha nui, a me ka nahu kuakoko, E nui loa auanei ko lakou eha, e like me ke kuakoko o ka wahine hanau keiki; E haka pono no kekahi i kekahi me ka makau, E like ana ko lakou maka me ka lapalapa ahi.
9 Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀ ọjọ́ búburú, pẹ̀lú ìbínú àti ìrunú gbígbóná— láti sọ ilẹ̀ náà dahoro, àti láti pa àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ inú rẹ̀ run.
Aia hoi! ka la o Iehova, ke hele mai la, He weliweli loa no ka ukiuki, a me ka inaina nui, E hoolilo i ka aina i auakua, A e anai aku i ka poe hewa.
10 Àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run àti ìkójọpọ̀ wọn kò sì ní fi ìmọ́lẹ̀ wọn hàn. Àṣẹ̀ṣẹ̀yọ oòrùn yóò di òkùnkùn àti òṣùpá kò ní fi ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ hàn.
O na hoku o ka lani a me na huihui ona, Aole lakou e haawi mai i ka malamalama; E poeleele no ka la i kona hele ana, Aole hoi e hoomalamalama mai ka mahina.
11 Èmi yóò jẹ ayé ní ìyà nítorí ibi rẹ̀, àwọn ìkà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Èmi yóò fi òpin sí gààrù àwọn agbéraga èmi ó sì rẹ ìgbéraga àwọn aláìláàánú sílẹ̀.
A e hoopai aku au i ka hewa maluna o ka aina, A i ko lakou hala hoi maluna o ka poe lawehala. E hooki no wau i ka manao kiekie o ka poe hookano, A e hoohaahaa hoi au i ka manao haakei o ka poe hookaumaha.
12 Èmi yóò jẹ́ kí ọkùnrin kí ó wọn ju ojúlówó wúrà lọ, yóò sì ṣọ̀wọ́n ju wúrà Ofiri lọ.
E hana aku au, a e uuku na kanaka, he nui ke gula, He uuku kanaka, he nui na gula o Opira.
13 Nítorí náà èmi yóò jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó wárìrì; ayé yóò sì mì tìtì ní ibùjókòó rẹ̀ láti ọwọ́ ìbínú Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ní ọjọ́ ìbínú gbígbóná rẹ.
No ka mea, e hoonaueue au i na lani, A e kulanalana ka honua mai kona wahi aku, No ka inaina o Iehova o na kaua, Ke hiki aku ka la o kona ukiuki wela.
14 Gẹ́gẹ́ bí egbin tí à ń dọdẹ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí àgùntàn tí kò ní olùṣọ́, ọ̀kọ̀ọ̀kan yóò padà tọ àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ, ọ̀kọ̀ọ̀kan yóò sá padà sí ilẹ̀ abínibí i rẹ̀.
E like ana hoi ia me ka dia i hahaiia, Me na hipa hoi, aohe mea nana lakou e hoiliili. E huli no kela mea keia mea i kona poe kanaka iho, E holo no kela mea keia mea i kona aina iho.
15 Ẹnikẹ́ni tí a bá gbámú ni a ó wọ́ nílẹ̀ tuurutu, gbogbo àwọn tí ọwọ́ bá tẹ̀ ni yóò ti ipa idà kú.
E houia na mea a pau i loaa; A o ka poe a pau i huiia'ku, e haule lakou i ka pahikaua.
16 Àwọn ọ̀dọ́mọdé wọn ni a ó fọ́ sí wẹ́wẹ́ níṣojú wọn, gbogbo ilẹ̀ wọn ni a ó kó àwọn aya wọn ni a ó sì bá dàpọ̀.
A e ulupaia ka la kou keiki imua o ko lakou mau maka; E haoia ko lakou hale, A e moe wale ia ka lakou mau wahine.
17 Kíyèsi i, èmi yóò ru àwọn Media sókè sí wọn, àwọn tí kò bìkítà fún fàdákà tí kò sì ní inú dídùn sí wúrà.
Aia hoi! e hoala no wau i ko Media e ku e ia lakou, I ka poe i manao ole i ke kala; A o ke gula hoi, aole lakou makemake ia mea.
18 Ọrùn wọn yóò ré àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin lulẹ̀; wọn kò ní ṣàánú àwọn ọ̀dọ́mọdé tàbí kí wọn síjú àánú wo àwọn ọmọdé.
Na ko lakou kakaka e kulai i na kanaka ui, Aole lakou e aloha i ka hua o ka opu; Aole e menemene ko lakou maka i na keiki uuku.
19 Babeli, ohun ọ̀ṣọ́ àwọn ìjọba ògo ìgbéraga àwọn ará Babeli ni Ọlọ́run yóò da ojú rẹ̀ bolẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Sodomu àti Gomorra.
O Babulona, ka mea nani o na aupuni, Ka mea e hanohano ai, a e kaena ai hoi o Kaledea, E like auanei ia me Sodoma a me Gomora, Na mea a ke Akua i hookahuli ai.
20 A kì yóò tẹ̀ ibẹ̀ dó mọ́ tàbí kí á gbé inú rẹ̀ láti ìrandíran; ará Arabia kì yóò pa àgọ́ níbẹ̀ mọ́, olùṣọ́-àgùntàn kan kì yóò kó ẹran rẹ̀ sinmi níbẹ̀.
E kanaka ole ana ia mai ia wa aku, Aole e noho hou ia, mai ia hanauna, a ia hanauna aku; Aole e kukulu hou ka Arabia i kona halelewa malaila, A malaila hoi, aole e hoomoe hou na kahuhipa i ka lakou hipa.
21 Ṣùgbọ́n àwọn ẹranko igbó ni yóò dùbúlẹ̀ níbẹ̀, àwọn ajáko yóò kún inú ilé wọn, níbẹ̀ ni àwọn òwìwí yóò máa gbé níbẹ̀ ni àwọn ewúrẹ́ igbó yóò ti máa bẹ́ kiri.
Malaila no e moe ai na holoholona o ka waonahele; A e piha no hoi ko lakou hale i na aoa; E noho no malaila ka iana, A e haa wale na kao hihiu malaila.
22 Ìkookò yóò máa gbó ní ibùba wọn, àwọn ajáko nínú arẹwà ààfin wọn.
E hae no na iliohae ma ko lakou halealii, A me na ilio hihiu ma ko lakou mau halelewa. Ua kokoke mai no kona manawa, Aole hoi e hooloihiia kona mau la.

< Isaiah 13 >