< Isaiah 12 >

1 Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé, “Èmi ó yìn ọ́, Olúwa. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ò ti bínú sí mi ìbínú rẹ ti yí kúrò níbẹ̀ ìwọ sì ti tù mí nínú.
I w tym dniu powiesz: Wysławiać cię będę, PANIE, bo choć gniewałeś się na mnie, odwróciłeś swój gniew i pocieszyłeś mnie.
2 Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi, èmi yóò gbẹ́kẹ̀lé e èmi kì yóò bẹ̀rù. Olúwa, Olúwa náà ni agbára à mi àti orin ìn mi, òun ti di ìgbàlà mi.”
Oto Bóg jest moim zbawieniem, zaufam i nie będę się lękał, gdyż JEHOWA BÓG jest moją mocą i [moją] pieśnią; i on stał się moim zbawieniem.
3 Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi láti inú kànga ìgbàlà.
Z radością więc będziecie czerpać wodę ze zdrojów zbawienia.
4 Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé, “Fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀, jẹ́ kí ó di mí mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun tí ó ti ṣe kí o sì kéde pé a ti gbé orúkọ rẹ̀ ga.
W tym dniu powiecie: Wysławiajcie PANA, wzywajcie jego imienia, rozgłaszajcie wśród ludów jego dzieła, przypominajcie, że jego imię jest wywyższone.
5 Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo, jẹ́ kí èyí di mí mọ̀ fún gbogbo ayé.
Śpiewajcie PANU, gdyż uczynił wielkie rzeczy. Niech będzie o tym wiadomo w całej ziemi.
6 Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni, nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo ti Israẹli láàrín yín.”
Wykrzykuj i śpiewaj, mieszkanko Syjonu! Wielki bowiem [jest] pośród ciebie Święty Izraela.

< Isaiah 12 >