< Isaiah 12 >

1 Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé, “Èmi ó yìn ọ́, Olúwa. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ò ti bínú sí mi ìbínú rẹ ti yí kúrò níbẹ̀ ìwọ sì ti tù mí nínú.
És szólsz ama napon: Hálát adok neked, Örökkévaló, mert haragudtál rám; elfordult haragod és megvigasztalsz engem.
2 Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi, èmi yóò gbẹ́kẹ̀lé e èmi kì yóò bẹ̀rù. Olúwa, Olúwa náà ni agbára à mi àti orin ìn mi, òun ti di ìgbàlà mi.”
Íme Isten, az én segítségem, bízom és nem rettegek; mert hatalmam és énekem Jáh, az Örökkévaló, ő lett nekem segítségül.
3 Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi láti inú kànga ìgbàlà.
És vizet fogtok meríteni vígsággal a segítség forrásából.
4 Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé, “Fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀, jẹ́ kí ó di mí mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun tí ó ti ṣe kí o sì kéde pé a ti gbé orúkọ rẹ̀ ga.
És szóltok ama napon: Adjatok hálát az Örökkévalónak, hirdessétek nevét, tudassátok a népek között cselekedeteit, emlegessétek, hogy magasztos a neve.
5 Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo, jẹ́ kí èyí di mí mọ̀ fún gbogbo ayé.
Zengjetek az Örökkévalónak, mert fenségeset cselekedett; tudtára van ez az egész földnek.
6 Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni, nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo ti Israẹli láàrín yín.”
Örvendj és ujjongj, Czión lakója, mert nagy tebenned Izrael szentje.

< Isaiah 12 >