< Isaiah 12 >
1 Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé, “Èmi ó yìn ọ́, Olúwa. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ò ti bínú sí mi ìbínú rẹ ti yí kúrò níbẹ̀ ìwọ sì ti tù mí nínú.
Amo esoga, Isala: ili dunu da gesami hea: mu, amane, “Hina Gode! Na Dima nodosa. Di da nama ougi galu. Be wali Dia da ougi yolesili, na dogo denesilala.
2 Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi, èmi yóò gbẹ́kẹ̀lé e èmi kì yóò bẹ̀rù. Olúwa, Olúwa náà ni agbára à mi àti orin ìn mi, òun ti di ìgbàlà mi.”
Gode da na Gaga: su dunu. Na da mae beda: ne, Ea hou dafawaneyale dawa: le, lalegagumu. Hina Gode da gasa bagade hou nama iaha. E da na Gaga: su dunu.
3 Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi láti inú kànga ìgbàlà.
Hano hanai dunu da hano noga: i nasea, hahawane bagade ba: sa. Amo defele, Gode da Ea fi dunu gaga: sea, ilia da hahawane bagade ba: sa.
4 Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé, “Fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀, jẹ́ kí ó di mí mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun tí ó ti ṣe kí o sì kéde pé a ti gbé orúkọ rẹ̀ ga.
Amo esoga, dilia Gode Ea fi dunu da amane gesami hea: mu, “Hina Godema nodoma! E da nini fidima: ne wele sia: ma! Ea hamoi amo fifi asi gala huluane ilima adoma. E da gasa bagadedafaba: le, ilima adoma!
5 Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo, jẹ́ kí èyí di mí mọ̀ fún gbogbo ayé.
E da gasa bagade hou hamobeba: le, Ema nodone gesami hea: ma. Osobo bagade fifi asi gala huluane da amo sia: ida: iwane gala nabimu da defea.
6 Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni, nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo ti Israẹli láàrín yín.”
Dunu huluanedafa Saione Goumi amoga esala, amo da wele sia: mu amola gesami hea: mu da defea. Isala: ili dunu fi ilia Hadigi Gode da Bagadedafa. Amola E da Ea fi amo ganodini esala.”