< Hosea 1 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Hosea ọmọ Beeri wá ní àkókò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah; àwọn ọba Juda àti ní àkókò ọba Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi ní Israẹli.
Judah siangpahrang Uzziah, Jotham, Ahaz hoi Hezekiah tinaw a bawi nah, Joash capa, Jeroboam ni Isarel siangpahrang a tawk nah Beeri capa Hosi koe ka tho e Cathut lawk teh,
2 Nígbà tí Olúwa bẹ̀rẹ̀ sí ní sọ̀rọ̀ láti ẹnu Hosea, Olúwa wí fún un pé, “Lọ, fẹ́ àgbèrè obìnrin kan fún ara rẹ, kí ó sì bí ọmọ àgbèrè fún ọ nípasẹ̀ àwọn ọkùnrin mìíràn, nítorí ilẹ̀ ti ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè púpọ̀ nípa yíyapa kúrò lọ́dọ̀ Olúwa.”
Nang ni cet nateh atak kâyawt e napui hoi a canaw hah na yu lah lat haw. Bangkongtetpawiteh, khocanaw ni Cathut a pahnawt awh teh boutbout a payon awh toe telah Hosi koe Cathut ni atipouh.
3 Nígbà náà ni ó sì lọ, ó sì fẹ́ Gomeri ọmọbìnrin Diblaimu, ọmọbìnrin náà sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan fún un.
Hosi ni Cathut ni a dei e patetlah a cei teh, Debalaim canu, Gomer hah a yu lah a la. A yu ni camo a vawn teh ca tongpa a khe.
4 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Hosea pé, “Pe orúkọ ọmọ náà ní Jesreeli, nítorí pé láìpẹ́ ni èmi yóò jẹ ìdílé Jehu ní ìyà fún ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn tó pa ní ìpakúpa ní Jesreeli, Èmi yóò sì mú ìjọba Israẹli wá sí òpin.
Hatnavah Cathut ni Hosi koe, hete camo e min teh Jezreel phung loe atipouh. Bangkongtetpawiteh a ro hoehnahlan Jezreel theinae phu teh Jehu imthung koe moi ka pathung vaiteh, Isarel ram a uknaeram tueng ka baw sak pouh awh han.
5 Ní ọjọ́ náà ni Èmi yóò ṣẹ́ ọrun Israẹli ní àfonífojì Jesreeli.”
Hahoi, Jezreel yawn dawk Isarel ransanaw e thaonae teh ka raphoe han telah a ti.
6 Gomeri sì tún lóyún, ó sì bí ọmọbìnrin kan. Olúwa sọ fún un pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Lo-ruhama, nítorí pé, Èmi kò ní ṣàánú fún ilé Israẹli mọ́, Èmi kò sì ní dáríjì wọ́n.
Gomer ni camo apâhni lah bout a vawn teh napui a khe. Bawipa ni min teh Loruhamah phung loe. Bangkongtetpawiteh, Isarelnaw teh ka pahren mahoeh toe, ka takhoe han toe.
7 Síbẹ̀, èmi yóò ṣàánú fún ilé Juda, èmi ó gbà wọ́n—kì í ṣe nípa ọfà, idà tàbí ogun, ẹṣin tàbí kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin bí kò ṣe nípa Olúwa Ọlọ́run wọn.”
Hatei, Kai ni Judahnaw teh ka pahren han. Ahnimae BAWIPA Cathut Kai ni ka rungngang han. Ka rungngang nah taran tuknae senehmaica, lilava, pala, tahloi, marangnaw, hoi marangransanaw ka hno mahoeh a ti.
8 Lẹ́yìn ìgbà tí ó gba ọmú lẹ́nu Lo-ruhama, ó sì lóyún ó sì bí ọmọkùnrin mìíràn. Nígbà náà ni
Gomer ni a canu hah sanu a pâphei hnukkhu, camo bout a vawn teh, ca tongpa a khe.
9 Olúwa sì sọ fún un pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Lo-Ammi, nítorí pé ẹ kì í ṣe ènìyàn mi, èmi náà kì í sì í ṣe Ọlọ́run yín.
Cathut ni Hosi koe, a min teh Loammi phung loe. Bangkongtetpawiteh, nangmouh teh, kaie tami nahoeh, kai hai nangmae Cathut nahoeh atipouh.
10 “Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli yóò pọ̀ bí i iyanrìn etí Òkun tí a kò le wọ́n, tí a kò sì le è kà, yóò sì ṣe. Ní ibi tí wọ́n ti sọ fún wọn pé. ‘Ẹ̀yin kì í ṣe ènìyàn mi,’ níbẹ̀ ni a ó ti máa pè wọ́n ní ‘Ọmọ Ọlọ́run alààyè.’
Isarelnaw teh palang sadi patetlah apung awh han. Bangnue thai hoeh e hoi touk thai hoeh e lah ao han. Atuvah, Cathut ni Isarelnaw teh ka tami nahoeh ati. Hatei, nangmouh teh kahring Cathut e canaw lah na o awh tie hnin ka phat han.
11 Àwọn ènìyàn Juda àti àwọn ènìyàn Israẹli yóò parapọ̀, wọn yóò sì yan olórí kan tí yóò jáde láti ilẹ̀ náà, nítorí pé ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ Jesreeli yóò jẹ́.
Judahnaw hoi Isarelnaw ni bout a kamkhueng awh han. Amamouh hanlah siangpahrang buet touh a rawi awh vaiteh, hete ram dawk hoi a tâco awh han. Jezreel se teh a lentoe han telah a ti.

< Hosea 1 >