< Hosea 1 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Hosea ọmọ Beeri wá ní àkókò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah; àwọn ọba Juda àti ní àkókò ọba Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi ní Israẹli.
BOEIPA ol tah Judah manghai rhoek Uzziah, Jotham, Ahaz, Hezekiah tue neh Israel manghai Joash capa Jeroboam tue vaengah Beeri capa Hosea taengla pawk.
2 Nígbà tí Olúwa bẹ̀rẹ̀ sí ní sọ̀rọ̀ láti ẹnu Hosea, Olúwa wí fún un pé, “Lọ, fẹ́ àgbèrè obìnrin kan fún ara rẹ, kí ó sì bí ọmọ àgbèrè fún ọ nípasẹ̀ àwọn ọkùnrin mìíràn, nítorí ilẹ̀ ti ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè púpọ̀ nípa yíyapa kúrò lọ́dọ̀ Olúwa.”
BOEIPA tah Hosea dong lamloh lamhma la cal. Te vaengah BOEIPA loh Hosea te, “Cet lamtah pumyoi nu neh pumyoihnah kah camoe rhoek te namah taengla lo laeh. Khohmuen he BOEIPA hnuk lamloh cukhalh rhoe cukhalh,” a ti nah.
3 Nígbà náà ni ó sì lọ, ó sì fẹ́ Gomeri ọmọbìnrin Diblaimu, ọmọbìnrin náà sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan fún un.
Te dongah cet tih Diblaim canu Gomer te a loh. Te vaengah vawn tih anih hamla capa pakhat a sak pah.
4 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Hosea pé, “Pe orúkọ ọmọ náà ní Jesreeli, nítorí pé láìpẹ́ ni èmi yóò jẹ ìdílé Jehu ní ìyà fún ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn tó pa ní ìpakúpa ní Jesreeli, Èmi yóò sì mú ìjọba Israẹli wá sí òpin.
Te vaengah BOEIPA loh anih te, “A ming te Jezreel sui. Jehu im kah Jezreel thii te ka cawh vetih Israel imkhui kah ram te ka paa sak pawn ni.
5 Ní ọjọ́ náà ni Èmi yóò ṣẹ́ ọrun Israẹli ní àfonífojì Jesreeli.”
Te khohnin te a pha vaengah tah Israel kah lii te Jezreel kol ah ka khaem pah ni,” a ti.
6 Gomeri sì tún lóyún, ó sì bí ọmọbìnrin kan. Olúwa sọ fún un pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Lo-ruhama, nítorí pé, Èmi kò ní ṣàánú fún ilé Israẹli mọ́, Èmi kò sì ní dáríjì wọ́n.
Te phoeiah koep vawn tih canu a sak hatah, “Israel imkhui te koep ka haidam voel pawt vetih amih te ka khuen rhoe ka khuen ham coeng dongah a ming te Loruhamah sui.
7 Síbẹ̀, èmi yóò ṣàánú fún ilé Juda, èmi ó gbà wọ́n—kì í ṣe nípa ọfà, idà tàbí ogun, ẹṣin tàbí kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin bí kò ṣe nípa Olúwa Ọlọ́run wọn.”
Tedae Judah imkhui tah ka haidam vetih amih te amamih kah Pathen BOEIPA rhangneh ka khang ni. Te vaengah amih te lii neh, tumca neh, caemtloek neh, marhang neh, marhang caem neh ka khang mahpawh,” a ti nah.
8 Lẹ́yìn ìgbà tí ó gba ọmú lẹ́nu Lo-ruhama, ó sì lóyún ó sì bí ọmọkùnrin mìíràn. Nígbà náà ni
Loruhamah te suk a kan phoeiah vawn tih capa a sak.
9 Olúwa sì sọ fún un pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Lo-Ammi, nítorí pé ẹ kì í ṣe ènìyàn mi, èmi náà kì í sì í ṣe Ọlọ́run yín.
Te vaengah, “Nangmih te ka pilnam voel pawt tih kai khaw nangmih hut la ka om voel pawt dongah a ming te Loami sui,” a ti nah.
10 “Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli yóò pọ̀ bí i iyanrìn etí Òkun tí a kò le wọ́n, tí a kò sì le è kà, yóò sì ṣe. Ní ibi tí wọ́n ti sọ fún wọn pé. ‘Ẹ̀yin kì í ṣe ènìyàn mi,’ níbẹ̀ ni a ó ti máa pè wọ́n ní ‘Ọmọ Ọlọ́run alààyè.’
Tedae Israel ca hlangmi tah tuitunli kah laivin bangla om ni. Te te loeng lek pawt tih tae lek pawh. Amih te, 'Nangmih te ka pilnam moenih,’ a ti nah hmuen ah a om sak vetih amih te aka hing Pathen ca rhoek a ti ni.
11 Àwọn ènìyàn Juda àti àwọn ènìyàn Israẹli yóò parapọ̀, wọn yóò sì yan olórí kan tí yóò jáde láti ilẹ̀ náà, nítorí pé ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ Jesreeli yóò jẹ́.
Te vaengah Judah ca rhoek neh Israel ca tun tingtun uh ni. Amamih ham boeilu pakhat a khueh uh tih Jezreel khohnin puei ham khohmuen lamloh cet uh ni,” a ti nah.

< Hosea 1 >