< Hosea 9 >

1 Má ṣe yọ̀, ìwọ Israẹli; má ṣe hó ìhó ayọ̀ bí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù. Nítorí ẹ ti jẹ́ aláìṣòótọ́ si Ọlọ́run yín. Ẹ fẹ́ràn láti gba owó iṣẹ́ àgbèrè ní gbogbo ilẹ̀ ìpakà.
Wee Isiraeli-rĩ, tiga gũkena; tiga gũkũngũĩra ta ndũrĩrĩ iria ingĩ. Nĩgũkorwo ũkoretwo ũtarĩ mwĩhokeku harĩ Ngai waku; wee nĩwendete mũcaara wa maraya, ũkaũcaragia kũrĩa guothe kũhuhagĩrwo ngano.
2 Àwọn ilẹ̀ ìpakà àti ilé ìfun wáìnì kò ní fún àwọn ènìyàn lóúnjẹ wáìnì tuntun yóò tàn láìròtẹ́lẹ̀.
Ihuhĩro cia ngano na ihihĩro cia ndibei itikahũũnia andũ, o na gũtigakorwo na ndibei ya mũhihano.
3 Wọn kò ní ṣẹ́kù sí ilé Olúwa Efraimu yóò padà sí Ejibiti, yóò sì jẹ oúnjẹ àìmọ́ ní Asiria.
Matigaatũũra bũrũri wa Jehova; Efiraimu agaacooka bũrũri wa Misiri, na arĩe irio irĩ thaahu kũu Ashuri.
4 Wọn kò ní fi ọrẹ ohun mímu fún Olúwa. Bẹ́ẹ̀ ni ìrúbọ wọn kò ní mú, inú rẹ̀ dùn. Ìrú ẹbọ bẹ́ẹ̀ yóò dàbí oúnjẹ àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀. Gbogbo àwọn tó bá sì jẹ ẹ́ yóò di aláìmọ́. Oúnjẹ yìí yóò wà fún wọn fúnra wọn kò ní wá sí orí tẹmpili Olúwa.
Matigaitĩra Jehova maruta ma ndibei, kana magongona mao mamũkenie. Kũrĩo magongona ta macio makaahaana ta mũgate wa andũ megũcakaya; arĩa othe makaamarĩa nĩmakanyiitwo nĩ thaahu. Irio icio igaakorwo irĩ ciao o ene; itikareehwo hekarũ-inĩ ya Jehova.
5 Kí ni ẹ̀yin ó ṣe ní ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn ní àwọn ọjọ́ àjọ̀dún Olúwa?
Mũgeeka atĩa mũthenya ũrĩa mwamũre wa ciathĩ cianyu, mĩthenya ĩyo ya gĩathĩ kĩa Jehova?
6 Bí wọ́n tilẹ̀ yọ́ kúrò lọ́wọ́ ìparun Ejibiti yóò kó wọn jọ, Memfisi yóò sì sin wọ́n. Ibi ìsọjọ̀ fàdákà wọn ni ẹ̀gún yóò jogún, Ẹ̀gún yóò bo àpótí ìṣúra fàdákà wọn. Ẹ̀gún yóò sì bo gbogbo àgọ́ wọn.
O na mangĩkaahonoka kwanangwo, andũ a bũrũri wa Misiri nĩmakamacookereria, nao andũ a Memufisi mamathike. Congʼe nĩguo ũgaacooka handũ ha igĩĩna ciao cia betha, nayo mĩigua ĩhumbĩre hema ciao.
7 Àwọn ọjọ́ ìjìyà ń bọ̀; àwọn ọjọ́ ìṣirò iṣẹ́ ti dé. Jẹ́ kí Israẹli mọ èyí. Nítorí pé ẹ̀ṣẹ̀ yín pọ̀ ìkórìíra yín sì pọ̀ gan an ni. A ka àwọn wòlíì sí òmùgọ̀, a ka ẹni ìmísí sí asínwín.
Matukũ ma kũherithio nĩmakinyu, ĩĩ, matukũ ma kũrĩhania nĩmakinyĩte. Isiraeli nĩamenye ũguo. Tondũ mehia manyu nĩ maingĩ mũno, na rũmena rwanyu rũkaneneha mũno, mũnabii akoonagwo arĩ mũndũ mũkĩĩgu, na mũndũ ũrĩa ũrĩ na ũrathi akonwo arĩ mũgũrũki.
8 Wòlíì, papọ̀ pẹ̀lú Ọlọ́run, ni olùṣọ́ ọ Efraimu. Síbẹ̀ ìdẹ̀kùn dúró dè é ní gbogbo ọ̀nà rẹ̀ àti ìkórìíra ní ilé Ọlọ́run rẹ̀.
Mũnabii nĩwe ũtuĩtwo mũrangĩri wa Efiraimu nĩ Ngai wakwa; no rĩrĩ, mĩtego ĩmwetereire njĩra-inĩ ciake ciothe, na rũmena rũkamweterera nyũmba-inĩ ya Ngai wake.
9 Wọ́n ti gbilẹ̀ nínú ìwà ìbàjẹ́ gẹ́gẹ́ bí i ọjọ́ Gibeah Ọlọ́run yóò rántí ìwà búburú wọn yóò sì jẹ wọ́n ní yà fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Nĩmatoonyereire, makarikĩra mũno ũũru-inĩ, o ta ũrĩa meekire matukũ-inĩ ma Gibea. Nake Ngai nĩakaririkana waganu wao, na amaherithie nĩ ũndũ wa mehia mao.
10 “Mo rí Israẹli bí èso àjàrà ní aginjù. Mo rí àwọn baba yín, bí àkọ́pọ́n nínú igi ọ̀pọ̀tọ́ ní àkọ́so rẹ̀. Ṣùgbọ́n wọ́n tọ Baali-Peori lọ, wọ́n yà wọn sọ́tọ̀ fún òrìṣà tó ń mú ìtìjú bá ni, ohun ìríra wọn sì rí gẹ́gẹ́ bí wọn ti fẹ́.
“Rĩrĩa ndaamenyire Isiraeli, kwarĩ ta mũndũ onete thabibũ werũ-inĩ; rĩrĩa ndonire maithe manyu-rĩ, kwarĩ ta mũndũ onete matunda ma mũtĩ wa mũkũyũ marĩa maambaga kwĩrua. No rĩrĩa Isiraeli mookire Baali-Peoru, nĩmeyamũrĩire mũhianano ũcio wa gĩconoko, na magĩthũka, magĩtuĩka o ta kĩndũ kĩu mendete.
11 Ògo Efraimu yóò fò lọ bí ẹyẹ kò ní sí ìfẹ́rakù, ìlóyún àti ìbímọ.
Riiri wa Efiraimu ũkoombũka ta nyoni ũũre: gũtigakorwo ũhoro wa gũciara, kana gũkuua nda, o na kana kũgĩa nda.
12 Bí wọ́n tilẹ̀ tọ́ ọmọ dàgbà. Èmi yóò mú wọn ṣọ̀fọ̀ lórí gbogbo wọn. Ègbé ni fún wọn, nígbà tí mo yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn!
O na mangĩkaarera ciana-rĩ, nĩngaciũraga ciothe. Rĩrĩa ngaagarũrũka ndĩmatige, kaĩ nĩmagakorwo na haaro-ĩ!
13 Mo rí Efraimu bí ìlú Tire tí a tẹ̀dó sí ibi dáradára ṣùgbọ́n Efraimu yóò kó àwọn ọmọ rẹ̀ jáde fún àwọn apànìyàn.”
Nĩnyonete Efiraimu, ahaandĩtwo handũ hega, o ta Turo. No rĩrĩ, Efiraimu akaaruta ciana ciake, acineane kũrĩ mũũragani.”
14 Fún wọn, Olúwa! Kí ni ìwọ yóò fún wọn? Fún wọn ní inú tí ń ba oyún jẹ́ àti ọyàn gbígbẹ.
Mahe, Wee Jehova; no nĩ kĩĩ ũkũmahe? Mahe nda iria ihunaga, na ũmahe nyondo iria itarĩ iria.
15 “Nítorí gbogbo ìwà búburú tí wọ́n hù ní Gilgali, Mo kórìíra wọn níbẹ̀, nítorí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Èmi yóò lé wọn jáde ní ilé mi, Èmi kò ní ní ìfẹ́ wọn mọ́ ọlọ̀tẹ̀ ni gbogbo olórí wọn.
“Nĩ ũndũ wa waganu wao wothe marĩ kũu Giligali, nĩkĩo ndamamenire marĩ o kũu. Nĩ ũndũ wa ciĩko ciao cia mehia-rĩ, nĩngamarutũrũra moime nyũmba yakwa, na ndigacooka kũmenda rĩngĩ; atongoria ao othe nĩ aremi.
16 Efraimu ti rẹ̀ dànù gbogbo rẹ̀ sì ti rọ, kò sì so èso. Bí wọ́n tilẹ̀ bímọ. Èmi ó pa àwọn ọmọ wọn tí wọ́n fẹ́ràn jùlọ.”
Andũ a Efiraimu nĩacine nĩ mbaa, naguo mũri wao nĩũhoohete, maticiaraga maciaro. O na mangĩciara ciana-rĩ, nĩngooraga ciana icio ciao mendete.”
17 Ọlọ́run mi yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀ nítorí pé wọn kò gbọ́rọ̀ sí i; wọn yóò sì di alárìnkiri láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.
Ngai wakwa nĩakamarega, nĩgũkorwo matiamwathĩkĩire; magaatuĩka andũ a kũũrũũraga ndũrĩrĩ-inĩ.

< Hosea 9 >