< Hosea 7 >

1 nígbà tí èmi ìbá mú Israẹli láradá. Ẹ̀ṣẹ̀ Efraimu ń farahàn ìwà búburú Samaria sì ń hàn síta. Wọ́n ń ṣe ẹ̀tàn, àwọn olè ń fọ́ ilé; àwọn ọlọ́ṣà ń jalè ní òpópónà;
Mǝn Ɵz hǝlⱪimning asaritini buzup taxlap, azadliⱪⱪa erixtürǝy degǝndǝ, Mǝn Israilni saⱪaytay degǝndǝ, Əmdi Əfraimning ⱪǝbiⱨliki, Samariyǝning rǝzillikimu axkarilinidu; Qünki ular aldamqiliⱪ ⱪilidu; Oƣrilar bolsa bɵsüp kiriwatidu, Ⱪaraⱪqilar topi sirtta bulangqiliⱪ ⱪiliwatidu.
2 ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ pé mo rántí gbogbo ìwà búburú wọn. Ẹ̀ṣẹ̀ wọn gbé wọn mì pátápátá; wọ́n wà níwájú mi nígbà gbogbo.
Ular kɵnglidǝ Mening ularning barliⱪ rǝzilliklirini esimdǝ tutⱪanliⱪimni oylimaydu; Ⱨazir ularning ⱪilmixliri ɵzlirini ⱪistawatidu; Bu ixlar kɵz aldimdidur.
3 “Wọ́n ń mú inú ọba dùn pẹ̀lú ìwà búburú wọn, àti inú ọmọ-aládé dùn pẹ̀lú irọ́ wọn.
Ular padixaⱨni rǝzillikliri bilǝn, Əmirlǝrni yalƣan gǝpliri bilǝn hursǝn ⱪilidu;
4 Alágbèrè ni gbogbo wọn wọ́n gbóná bí ààrò àkàrà tí a dáwọ́ kíkoná dúró, lẹ́yìn ìgbà tí o ti pò ìyẹ̀fun tán, títí ìgbà tí yóò wú.
Ularning ⱨǝmmisi zinahorlar; Ular naway ot salƣan tonurdǝk; Naway hemirni yuƣurup, hemir bolƣuqǝ uning otini yǝnǝ ulƣaytmaydu;
5 Ní ọjọ́ àjọ̀dún ọba wa wáìnì mú ara ọmọ-aládé gbóná ó sì darapọ̀ mọ́ àwọn oníyẹ̀yẹ́.
Padixaⱨimiz [tǝbriklǝngǝn] künidǝ, ǝmirlǝr xarabning kǝypi bilǝn ɵzlirini zǝiplǝxtürdi; [Padixaⱨ] bolsa mazaⱪ ⱪilƣuqilar bilǝn ⱪol elixixⱪa intildi!
6 Ọkàn wọn ń gbóná bí i ààrò wọ́n sì tọ̀ ọ́ lọ pẹ̀lú rìkíṣí, ìbínú wọn pa lọ́lọ́ ní gbogbo òru ó sì bú jáde bí ọ̀wọ́-iná ní òwúrọ̀.
Qünki ular kɵnglini tonurdǝk ⱪizitip suyiⱪǝst püküp ⱪoyƣanidi; Keqiqǝ ularning ƣǝzipi qoƣlinip turidu; Sǝⱨǝrdila u yanƣan ottǝk yalⱪunlap ketidu.
7 Gbogbo wọn gbóná bí ààrò wọ́n pa gbogbo olórí wọn run, gbogbo ọba wọn si ṣubú kò sì ṣí ẹnìkan nínú wọn tí ó ké pè mí.
Ularning ⱨǝmmisi tonurdǝk ⱪiziⱪtur, ular ɵz soraⱪqilirini yǝp ketidu; Ularning barliⱪ padixaⱨliri yiⱪildi — Ulardin ⱨeqkim meni nida ⱪilip qaⱪirmaydu!
8 “Efraimu ti darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn náà; Efraimu jẹ́ àkàrà tí a kò yípadà.
Əfraim yat ⱪowmlar bilǝn arilixip kǝtti; U «ɵrülmigǝn bir ⱪoturmaq»dǝktur.
9 Àwọn àlejò ti jẹ agbára rẹ̀ run ṣùgbọ́n kò sì mọ̀. Ewú ti wà ní orí rẹ̀ káàkiri bẹ́ẹ̀ ni kò kíyèsi i.
Yat adǝmlǝr uning küqini yǝp kǝtti, biraⱪ u ⱨeq sǝzmǝydu; Bǝrⱨǝⱪ, [bexining] u yǝr-bu yeridǝ aⱪ qaqlar kɵrünidu, biraⱪ u ⱨeq bilmǝydu;
10 Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí sí i ṣùgbọ́n pẹ̀lú gbogbo èyí kò padà sí ọ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run, tàbí kí ó wá a.
Xuning bilǝn Israilning tǝkǝbburluⱪi ɵzigǝ ⱪarxi guwaⱨ beridu; Ular Pǝrwǝrdigar Hudasining yeniƣa ⱪaytmaydu; Yaki xundaⱪ ixlar [bexiƣa] qüxkǝn bolsimu, yǝnila Uni izdimǝydu.
11 “Efraimu dàbí àdàbà tó rọrùn láti tànjẹ àti aláìgbọ́n tó wá ń pé Ejibiti nísinsin yìí tó sì tún ń padà lọ si Asiria.
Əfraim ⱨeq ǝⱪli yoⱪ nadan bir pahtǝktǝk; Misirƣa ⱪarap sayraydu, Asuriyǝni izdǝp baridu;
12 Nígbà tí wọ́n bá lọ, èmi ó ta àwọ̀n mi sórí wọn, Èmi ó fà wọ́n lulẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹyẹ ojú ọ̀run. Nígbà tí mo bá gbọ́ pé wọ́n rìn pọ̀, Èmi ó nà wọ́n fún iṣẹ́ búburú ọwọ́ wọn.
Ular barƣanda, ularning üstigǝ torumni taxlaymǝn; Huddi asmandiki uqar-ⱪanatlarni torƣa qüxürgǝndǝk ularni qüxürimǝn; [Bu hǝwǝr] ularning jamaitigǝ yetixi bilǝnla, ularni jazalaymǝn.
13 Ègbé ní fún wọn, nítorí pé wọ́n ti yà kúrò lọ́dọ̀ mi! Ìparun wà lórí wọn, nítorí pé wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi! Èmi fẹ́ láti rà wọ́n padà. Ṣùgbọ́n wọ́n ń parọ́ mọ́ mi.
Ularƣa way! Qünki ular Mǝndin yiraⱪlixip tenip kǝtti! Ular ⱨalak bolsun! Qünki ular Manga wapasizliⱪ ⱪildi! Mǝn ularni ⱪutⱪuzup ⱨɵrlükkǝ qiⱪiray degǝndǝ, Ular Mǝn toƣruluⱪ yalƣan gǝp ⱪilidu!
14 Wọn kò kégbe pè mí láti ọkàn wọn, ṣùgbọ́n wọ́n ń pohùnréré ẹkún lórí ibùsùn wọn. Wọ́n kó ara wọn jọ, nítorí ọkà àti wáìnì ṣùgbọ́n wọ́n yípadà kúrò ní ọ̀dọ̀ mi.
Ular ornida yetip nalǝ ⱪilƣanda, Manga kɵnglidǝ ⱨeq nida ⱪilmidi; Ularning jamaǝtkǝ yiƣilixi pǝⱪǝt ax wǝ yengi xarab üqündur, halas; Ular Mǝndin qǝtlǝp kǝtti.
15 Mo kọ́ wọn, mo sì fún wọn ní agbára, síbẹ̀ wọ́n tún ń dìtẹ̀ mọ́ mi.
Bǝrⱨǝⱪ, Mǝn ǝsli ularni tǝrbiyiligǝnmǝn, Ularning bilǝklirini qeniⱪturup küqǝytküzgǝnidim; Biraⱪ ular Manga ⱪarxi yamanliⱪ ⱪǝstlǝwatidu.
16 Wọn kò padà sí ọ̀dọ̀ Ọ̀gá-ògo; wọ́n dàbí ọfà tí ó ti bàjẹ́. Àwọn aṣíwájú wọn yóò ti ipa idà ṣubú nítorí ìrunú ahọ́n wọn. Torí èyí, wọn ó fi wọ́n ṣe ẹlẹ́yà ní ilẹ̀ Ejibiti.
Ular buruldi — biraⱪ buruluxi Ⱨǝmmidin Aliy Bolƣuqiƣa ⱪaytix üqün ǝmǝs; Ular aldamqi bir oⱪyaƣa ohxax. Ularning ǝmirliri ɵzlirining ƣaljiranǝ til-aⱨanǝtliri wǝjidin ⱪiliqlinidu; Bu ix Misir zeminida ularni mǝshirigǝ ⱪalduridu.

< Hosea 7 >