< Hosea 6 >
1 “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a padà sọ́dọ̀ Olúwa ó ti fà wá ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ ṣùgbọ́n yóò mú wa láradá Ó ti pa wá lára ṣùgbọ́n yóò dí ojú ọgbẹ́ wa.
Ja, i sin nöd skola de söka mig: »Kommen, låtom oss vända om till HERREN. Ty han har sargat oss, han skall ock hela oss. Han har slagit oss, han skall ock förbinda oss.
2 Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ wá jí ní ọjọ́ kẹta yóò mú wa padà bọ̀ sípò kí a ba à le wá gbé níwájú rẹ̀.
Han skall om två dagar åter göra oss helbrägda; ja, på tredje dagen skall han låta oss stå upp, så att vi få leva inför honom.
3 Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa; ẹ jẹ́ kí a tẹ̀síwájú láti mọ̀ ọ́n. Gẹ́gẹ́ bí oòrùn ṣe ń yọ, yóò jáde; yóò tọ̀ wá wá bí òjò, bí òjò àkọ́rọ̀ ti ń bomirin ilẹ̀.”
Så låtom oss lära känna HERREN, ja, låtom oss fara efter att lära känna honom. Hans uppgång är så viss som morgonrodnadens, och han skall komma över oss lik ett regn, lik ett vårregn, som vattnar jorden.»
4 “Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Efraimu? Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Juda? Ìfẹ́ rẹ dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀ bí ìrì ìdájí tí ó kọjá lọ kíákíá.
Vad skall jag taga mig till med dig Efraim? Vad skall jag taga mig till med dig, Juda? Eder kärlek är ju lik morgonskyn, lik daggen, som tidigt försvinner.
5 Nítorí náà ni mo ṣe gé e yín sí wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì, Mo pa yín pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ẹnu mi, ìdájọ́ mi tàn bí i mọ̀nàmọ́ná lórí yín.
Därför har jag utdelat mina hugg genom profeterna, därför har jag dräpt dem genom min muns tal; så skall domen över dig stå fram i ljuset.
6 Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ; àti ìmọ̀ Ọlọ́run ju ọrẹ ẹbọ sísun lọ.
Ty jag har behag till kärlek och icke till offer, och till Guds kunskap mer än till brännoffer.
7 Bí i Adamu, wọ́n da májẹ̀mú wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí mi níbẹ̀.
Men dessa hava på människovis överträtt förbundet; däri hava de handlat trolöst mot mig.
8 Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀, a sí ti fi ẹ̀ṣẹ̀ bà á jẹ́.
Gilead är en stad av ogärningsmän, den är full med blodiga spår.
9 Bí adigunjalè ṣe ń ba ní bùba de àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ ni àwọn àlùfáà, ń parapọ̀; tí wọ́n sì ń pànìyàn lójú ọ̀nà tó lọ sí Ṣekemu, tí wọ́n sì ń dá ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ni lójú.
Och lik en rövarskara, som ligger i försåt för människor, är prästernas hop. De mörda på vägen till Sikem, ja, vad skändligt är göra de.
10 Mo ti rí ohun tó ba ni lẹ́rù ní ilé Israẹli. Níbẹ̀ Efraimu, fi ara rẹ̀ fún àgbèrè Israẹli sì di aláìmọ́.
I Israels hus har jag sett gruvliga ting; där bedriver Efraim sin otukt, där orenar sig Israel.
11 “Àti fún ìwọ, Juda, a ti yan ọjọ́ ìkórè rẹ. “Nígbà tí mo bá fẹ́ dá ohun ìní àwọn ènìyàn mi padà,
Också för dig, Juda, är en skördetid bestämd, när jag åter upprättar mitt folk.