< Hosea 6 >

1 “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a padà sọ́dọ̀ Olúwa ó ti fà wá ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ ṣùgbọ́n yóò mú wa láradá Ó ti pa wá lára ṣùgbọ́n yóò dí ojú ọgbẹ́ wa.
Tho awh, Cathut koe ban awh sei. Bawipa ni vekrasen lah na kei teh na phi ei, bout na dam sak han. Na hem eiteh, bout na sat han.
2 Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ wá jí ní ọjọ́ kẹta yóò mú wa padà bọ̀ sípò kí a ba à le wá gbé níwájú rẹ̀.
Hnin hni touh a loum hnukkhu na hring sak teh, hnin thum hnin vah, na thaw sak han. Hatdawkvah, ama koe maimouh teh hring awh han. Lungangnae hai tawn awh han.
3 Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa; ẹ jẹ́ kí a tẹ̀síwájú láti mọ̀ ọ́n. Gẹ́gẹ́ bí oòrùn ṣe ń yọ, yóò jáde; yóò tọ̀ wá wá bí òjò, bí òjò àkọ́rọ̀ ti ń bomirin ilẹ̀.”
Cathut panue nahanlah a tawng awh han. A tâconae tueng teh amom patetlah ao. Kho ka rak e patetlah kho ahnoung e kho ka rak e patetlah talai duk sak hanlah a tho han
4 “Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Efraimu? Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Juda? Ìfẹ́ rẹ dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀ bí ìrì ìdájí tí ó kọjá lọ kíákíá.
Oe Ephraim, nang dawk bangmaw ka sak han. Oe Judah, nang dawk bangmaw ka sak han. Nangmae yuemkamcunae teh, amom e tâmai hoi, palang kahmat e tadamtui patetlah ao.
5 Nítorí náà ni mo ṣe gé e yín sí wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì, Mo pa yín pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ẹnu mi, ìdájọ́ mi tàn bí i mọ̀nàmọ́ná lórí yín.
Hatdawkvah, ahnimanaw hah profetnaw hno lahoi kai ni patpat ka bouk toe. Ka lawk tâcawt e lahoi ka thei toe. Lawkcengnae hai angnae patetlah ao toe.
6 Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ; àti ìmọ̀ Ọlọ́run ju ọrẹ ẹbọ sísun lọ.
Thuengnae hlak lungmanae, hmaisawi thuengnae hlak Cathut hoi kâpanuenae hah ka ngai.
7 Bí i Adamu, wọ́n da májẹ̀mú wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí mi níbẹ̀.
Ahnimouh teh, Adam patetlah lawkkam a tapoe awh toe. A o awhnae koe yuemkamcu hoeh lah na o sin awh toe.
8 Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀, a sí ti fi ẹ̀ṣẹ̀ bà á jẹ́.
Gilead khopui teh kahawihoeh hno ka saknaw e hmuen lah ao teh, tami thi kapalawngnaw e khokhnuk tungkâtue.
9 Bí adigunjalè ṣe ń ba ní bùba de àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ ni àwọn àlùfáà, ń parapọ̀; tí wọ́n sì ń pànìyàn lójú ọ̀nà tó lọ sí Ṣekemu, tí wọ́n sì ń dá ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ni lójú.
Dingcanaw ni kahlong kacetnaw a pawp awh e patetlah vaihmanaw ni Shekhem lah ceinae lam dawk patenghai tami a thei awh toe.
10 Mo ti rí ohun tó ba ni lẹ́rù ní ilé Israẹli. Níbẹ̀ Efraimu, fi ara rẹ̀ fún àgbèrè Israẹli sì di aláìmọ́.
Atangcalah, kahawihoeh hno a sak awh. Isarelnaw koe taki ka tho e hno ka hmu toe. Ephraimnaw a tak a kâyo teh, Isarel teh a khin.
11 “Àti fún ìwọ, Juda, a ti yan ọjọ́ ìkórè rẹ. “Nígbà tí mo bá fẹ́ dá ohun ìní àwọn ènìyàn mi padà,
Hothloilah, Oe Judahnaw, man lah kaawm e ka taminaw bout ka thokhai toteh, nang hanlah canganae tueng khoe lah ao.

< Hosea 6 >