< Hosea 5 >

1 “Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yìn àlùfáà! Ẹ fetísílẹ̀ ẹ̀yin ọmọ Israẹli! Ẹ gbọ́, ẹ̀yìn ilé ọba! Ìdájọ́ yìí kàn yín. Ẹ ti jẹ́ ẹ̀bìtì ní Mispa àwọ̀n ti a nà sílẹ̀ lórí Tabori.
Аскултаць лукрул ачеста, преоць! Я аминте, каса луй Исраел! Ши плякэ урекя, каса ымпэратулуй! Кэч пе вой вэ аменинцэ жудеката, пентру кэ аць фост о курсэ ла Мицпа ши ун лац ынтинс пе Табор!
2 Àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti gbilẹ̀ nínú ìpànìyàn gbogbo wọn ni èmi ó bá wí,
Некрединчоший се афундэ ын нелеӂюире, дар вой авя Еу педепсе пентру тоць!
3 mo mọ ohun gbogbo nípa Efraimu Israẹli kò sì pamọ́ fún mi Efraimu, ní báyìí ó ti ṣe àgbèrè Israẹli sì ti díbàjẹ́.
Куноск Еу доар пе Ефраим ши Исраел ну-Мь есте аскунс; штиу кэ ту, Ефраиме, ай курвит ши кэ Исраел с-а спуркат.
4 “Ìṣe wọn kò gbà wọ́n láààyè láti padà sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wọn. Ẹ̀mí àgbèrè wà ni ọkàn wọn, wọn kò sì mọ Olúwa.
Фаптеле лор ну ле ынгэдуе сэ се ынтоаркэ ла Думнезеул лор, кэч ун дух де курвие есте ын инима лор ши ну куноск пе Домнул!
5 Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí lé wọn; àwọn ọmọ Israẹli, àti Efraimu pàápàá kọsẹ̀ nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Juda náà sì kọsẹ̀ pẹ̀lú wọn.
Дар мындрия луй Исраел ва фи марторэ ымпотрива луй, ши Исраел ши Ефраим вор кэдя прин нелеӂюиря лор, ши Иуда ва кэдя ши ел ку ей.
6 Nígbà tí wọ́n bá lọ pẹ̀lú agbo ẹran àti ọ̀wọ́ ẹran wọn láti wá Olúwa, wọn kò ní rí i, ó ti yọ ara rẹ̀ kúrò láàrín wọn.
Вор мерӂе ку оиле ши боий лор сэ кауте пе Домнул, дар ну-Л вор гэси ничдекум, кэч С-а депэртат дин мижлокул лор.
7 Wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Olúwa wọ́n sì bí àwọn àjèjì ọmọ. Nísinsin yìí, ọdún oṣù tuntun wọn, ni yóò pa wọn run pẹ̀lú ìpín wọn.
Ау фост некрединчошь Домнулуй, кэч ау нэскут копий дин курвие; акум ый ва ынгици о лунэ ноуэ ку авуцииле лор.
8 “Fọn fèrè ní Gibeah, kí ẹ sì fun ìpè ní Rama. Ẹ pariwo ogun ní Beti-Afeni; máa wárìrì, ìwọ Benjamini.
Сунаць дин трымбицэ ла Гибея, сунаць дин трымбицэ ла Рама! Стригаць ла Бет-Авен! Ятэ-й пе урма та, Бениамине!
9 Efraimu yóò di ahoro ní ọjọ́ ìbáwí láàrín àwọn ẹ̀yà Israẹli, Mo sọ ohun tí ó dájú.
Ефраим ва фи пустиит ын зиуа педепсей; че вестеск Еу ымпотрива семинциилор луй Исраел ва вени негрешит!
10 Àwọn olórí Juda dàbí àwọn tí í máa yí òkúta ààlà kúrò. Èmi ó tú ìbínú gbígbóná mi lé wọn lórí bí ìkún omi.
Кэпетенииле луй Иуда сунт ка чей че мутэ семнул де ла хотаре; ка апа Ымь вой вэрса мыния песте ей!
11 A ni Efraimu lára, a sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ ní ìdájọ́, nítorí pé, ó pinnu láti tẹ̀lé òrìṣà.
Ефраим есте асуприт, здробит ын жудекатэ, кэч а урмат ынвэцэтуриле каре-й плэчяу.
12 Mo dàbí kòkòrò aṣọ sí Efraimu, Mo sì dàbí ìdin ara Juda.
Вой фи ка о молие пентру Ефраим, ка о путрезичуне (а динцилор) пентру каса луй Иуда.
13 “Nígbà ti Efraimu ri àìsàn rẹ̀, tí Juda sì rí ojú egbò rẹ̀ ni Efraimu bá tọ ará Asiria lọ, ó sì ránṣẹ́ sí ọba ńlá náà fún ìrànlọ́wọ́. Ṣùgbọ́n kò le è wò ó sàn bẹ́ẹ̀ ni kò le wo ojú egbò rẹ̀ jinná.
Кынд ышь веде Ефраим боала ши Иуда рэниле, Ефраим аляргэ ын Асирия ши тримите ла ымпэратул Иареб, мэкар кэ ымпэратул ачеста ну поате нич сэ вэ факэ сэнэтошь, нич сэ вэ лекуяскэ рэниле.
14 Nítorí pé, èmi ó dàbí kìnnìún sí Efraimu, bí i kìnnìún ńlá sí ilé Juda. Èmi ó fà wọ́n ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ èmi ó sì lọ; Èmi ó gbé wọn lọ, láìsí ẹni tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀.
Вой фи ка ун леу пентру Ефраим ши ка ун пуй де леу пентру каса луй Иуда; Еу, да, Еу вой сфышия ши апой вой плека, вой луа ши нимень ну-Мь ва рэпи прада.
15 Nígbà náà ni èmi ó padà lọ sí ààyè mi títí di ìgbà tí wọn ó fi gbà pé àwọn jẹ̀bi wọn yóò sì wá ojú mi nínú ìpọ́njú wọn, wọn ó fi ìtara wá mi.”
Вой плека, Мэ вой ынтоарче ын локуинца Мя пынэ кынд вор мэртуриси кэ сунт виноваць ши вор кэута Фаца Мя. Кынд вор фи ын неказ, вор алерга ла Мине.”

< Hosea 5 >