< Hosea 5 >

1 “Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yìn àlùfáà! Ẹ fetísílẹ̀ ẹ̀yin ọmọ Israẹli! Ẹ gbọ́, ẹ̀yìn ilé ọba! Ìdájọ́ yìí kàn yín. Ẹ ti jẹ́ ẹ̀bìtì ní Mispa àwọ̀n ti a nà sílẹ̀ lórí Tabori.
“Ouçam isto, seus padres! Ouça, casa de Israel, e dar ouvidos, casa do rei! Pois o julgamento é contra você; pois você tem sido um laço em Mizpah, e um spread líquido no Tabor.
2 Àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti gbilẹ̀ nínú ìpànìyàn gbogbo wọn ni èmi ó bá wí,
Os rebeldes estão profundamente abatidos, mas eu disciplino todos eles.
3 mo mọ ohun gbogbo nípa Efraimu Israẹli kò sì pamọ́ fún mi Efraimu, ní báyìí ó ti ṣe àgbèrè Israẹli sì ti díbàjẹ́.
Eu conheço o Ephraim, e Israel não é escondido de mim; por enquanto, Ephraim, você fez de prostituta. Israel está contaminado.
4 “Ìṣe wọn kò gbà wọ́n láààyè láti padà sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wọn. Ẹ̀mí àgbèrè wà ni ọkàn wọn, wọn kò sì mọ Olúwa.
Seus atos não permitirão que se voltem para seu Deus, pois o espírito da prostituição está dentro deles, e eles não conhecem Yahweh.
5 Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí lé wọn; àwọn ọmọ Israẹli, àti Efraimu pàápàá kọsẹ̀ nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Juda náà sì kọsẹ̀ pẹ̀lú wọn.
O orgulho de Israel testemunha seu rosto. Portanto, Israel e Efraim tropeçarão em sua iniqüidade. Judah também tropeçará com eles.
6 Nígbà tí wọ́n bá lọ pẹ̀lú agbo ẹran àti ọ̀wọ́ ẹran wọn láti wá Olúwa, wọn kò ní rí i, ó ti yọ ara rẹ̀ kúrò láàrín wọn.
Eles irão com seus rebanhos e com seus rebanhos em busca de Yahweh, mas eles não o encontrarão. Ele se retirou deles.
7 Wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Olúwa wọ́n sì bí àwọn àjèjì ọmọ. Nísinsin yìí, ọdún oṣù tuntun wọn, ni yóò pa wọn run pẹ̀lú ìpín wọn.
Eles são infiéis a Iavé; pois eles tiveram filhos ilegítimos. Agora a lua nova vai devorá-los com seus campos.
8 “Fọn fèrè ní Gibeah, kí ẹ sì fun ìpè ní Rama. Ẹ pariwo ogun ní Beti-Afeni; máa wárìrì, ìwọ Benjamini.
“Assopre a corneta em Gibeah, e a trombeta em Ramah! Soe um grito de batalha em Beth Aven, atrás de você, Benjamin!
9 Efraimu yóò di ahoro ní ọjọ́ ìbáwí láàrín àwọn ẹ̀yà Israẹli, Mo sọ ohun tí ó dájú.
Ephraim se tornará uma desolação no dia da repreensão. Entre as tribos de Israel, eu fiz saber o que certamente será.
10 Àwọn olórí Juda dàbí àwọn tí í máa yí òkúta ààlà kúrò. Èmi ó tú ìbínú gbígbóná mi lé wọn lórí bí ìkún omi.
Os príncipes de Judá são como aqueles que removem um marco histórico. Eu derramarei minha ira sobre eles como água.
11 A ni Efraimu lára, a sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ ní ìdájọ́, nítorí pé, ó pinnu láti tẹ̀lé òrìṣà.
Ephraim é oprimido, ele é esmagado no julgamento, porque ele tem a intenção de perseguir ídolos.
12 Mo dàbí kòkòrò aṣọ sí Efraimu, Mo sì dàbí ìdin ara Juda.
Therefore Eu sou para Efraim como uma traça, e para a casa de Judá como podridão.
13 “Nígbà ti Efraimu ri àìsàn rẹ̀, tí Juda sì rí ojú egbò rẹ̀ ni Efraimu bá tọ ará Asiria lọ, ó sì ránṣẹ́ sí ọba ńlá náà fún ìrànlọ́wọ́. Ṣùgbọ́n kò le è wò ó sàn bẹ́ẹ̀ ni kò le wo ojú egbò rẹ̀ jinná.
“Quando Efraim viu sua doença, e Judah sua ferida, então Efraim foi para a Assíria, e enviado ao Rei Jareb: mas ele não é capaz de curar você, nem ele irá curá-lo de sua ferida.
14 Nítorí pé, èmi ó dàbí kìnnìún sí Efraimu, bí i kìnnìún ńlá sí ilé Juda. Èmi ó fà wọ́n ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ èmi ó sì lọ; Èmi ó gbé wọn lọ, láìsí ẹni tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀.
Pois eu serei para Efraim como um leão, e como um leão jovem para a casa de Judá. Eu mesmo me desfaço em pedaços e vou embora. Eu irei embora, e não haverá ninguém para entregar.
15 Nígbà náà ni èmi ó padà lọ sí ààyè mi títí di ìgbà tí wọn ó fi gbà pé àwọn jẹ̀bi wọn yóò sì wá ojú mi nínú ìpọ́njú wọn, wọn ó fi ìtara wá mi.”
Eu irei e retornarei ao meu lugar, até que eles reconheçam sua ofensa, e procurar meu rosto. Em sua aflição, eles me procurarão com seriedade”.

< Hosea 5 >