< Hosea 5 >
1 “Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yìn àlùfáà! Ẹ fetísílẹ̀ ẹ̀yin ọmọ Israẹli! Ẹ gbọ́, ẹ̀yìn ilé ọba! Ìdájọ́ yìí kàn yín. Ẹ ti jẹ́ ẹ̀bìtì ní Mispa àwọ̀n ti a nà sílẹ̀ lórí Tabori.
“Iguai ũhoro ũyũ, inyuĩ athĩnjĩri-Ngai! Tegai matũ, inyuĩ andũ a Isiraeli! Thikĩrĩria, wee nyũmba ya ũthamaki! Nĩ inyuĩ mũgũtuĩrwo ciira ũyũ: Mũkoretwo mũrĩ mũtego kũu Mizipa, na mũrĩ wabu ya gũtegana yarĩtwo kũu Taboru.
2 Àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti gbilẹ̀ nínú ìpànìyàn gbogbo wọn ni èmi ó bá wí,
Aregi a watho nĩmarikĩire ũragani-inĩ. Niĩ nĩngamaherithia othe.
3 mo mọ ohun gbogbo nípa Efraimu Israẹli kò sì pamọ́ fún mi Efraimu, ní báyìí ó ti ṣe àgbèrè Israẹli sì ti díbàjẹ́.
Niĩ nĩnjũũĩ maũndũ mothe ma Efiraimu; Isiraeli ndahithĩtwo kuuma kũrĩ niĩ. Wee Efiraimu, rĩu nĩũhũrĩte ũmaraya; Isiraeli nake nĩathũkĩte.
4 “Ìṣe wọn kò gbà wọ́n láààyè láti padà sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wọn. Ẹ̀mí àgbèrè wà ni ọkàn wọn, wọn kò sì mọ Olúwa.
“Ciĩko ciao itingĩmetĩkĩria gũcookerera Ngai wao. Roho wa ũmaraya ũrĩ ngoro-inĩ ciao, nao makaaga kũmenya Jehova.
5 Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí lé wọn; àwọn ọmọ Israẹli, àti Efraimu pàápàá kọsẹ̀ nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Juda náà sì kọsẹ̀ pẹ̀lú wọn.
Mwĩtĩĩo wa Isiraeli nĩũrutaga ũira wa kũmookĩrĩra; andũ a Isiraeli na Efiraimu mahĩngagwo nĩ mehia mao; Juda o nake akahĩngwo hamwe nao.
6 Nígbà tí wọ́n bá lọ pẹ̀lú agbo ẹran àti ọ̀wọ́ ẹran wọn láti wá Olúwa, wọn kò ní rí i, ó ti yọ ara rẹ̀ kúrò láàrín wọn.
Hĩndĩ ĩrĩa magaathiĩ na ndũũru ciao cia mbũri na cia ngʼombe kũrongooria Jehova-rĩ, matikamuona; we nĩamehereire.
7 Wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Olúwa wọ́n sì bí àwọn àjèjì ọmọ. Nísinsin yìí, ọdún oṣù tuntun wọn, ni yóò pa wọn run pẹ̀lú ìpín wọn.
Nĩmagĩte kwĩhokeka harĩ Jehova; nao magaciara ciana itarĩ na ũngai. Na rĩrĩ, ciathĩ ciao cia Karũgamo ka Mweri nĩikaamameria, o hamwe na mĩgũnda yao.
8 “Fọn fèrè ní Gibeah, kí ẹ sì fun ìpè ní Rama. Ẹ pariwo ogun ní Beti-Afeni; máa wárìrì, ìwọ Benjamini.
“Huhai karumbeta kũu Gibea, na mũhuhe coro kũu Rama. Muuge mbu ya gwĩtana mbaara kũu Bethi-Aveni; wee Benjamini, wĩhũũge.
9 Efraimu yóò di ahoro ní ọjọ́ ìbáwí láàrín àwọn ẹ̀yà Israẹli, Mo sọ ohun tí ó dájú.
Efiraimu nĩgũgakira ihooru mũthenya ũcio wa ituĩro. Gatagatĩ-inĩ ka mĩhĩrĩga ya Isiraeli-rĩ, niĩ ngwanĩrĩra ũrĩa kũrĩ.
10 Àwọn olórí Juda dàbí àwọn tí í máa yí òkúta ààlà kúrò. Èmi ó tú ìbínú gbígbóná mi lé wọn lórí bí ìkún omi.
Atongoria a Juda mahaana andũ arĩa meheragia mahiga ma mĩhaka. Nĩngamaitĩrĩria mangʼũrĩ makwa, taarĩ kĩguũ kĩa maaĩ.
11 A ni Efraimu lára, a sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ ní ìdájọ́, nítorí pé, ó pinnu láti tẹ̀lé òrìṣà.
Efiraimu nĩmũhinyĩrĩrie, akarangĩrĩrio ituĩro-inĩ rĩa ciira, nĩ ũndũ wa kwenda kũrũmĩrĩra mĩhianano.
12 Mo dàbí kòkòrò aṣọ sí Efraimu, Mo sì dàbí ìdin ara Juda.
Niĩ haana memenyi kũrĩ Efiraimu, na ngahaana ta ũbuthu kũrĩ andũ a Juda.
13 “Nígbà ti Efraimu ri àìsàn rẹ̀, tí Juda sì rí ojú egbò rẹ̀ ni Efraimu bá tọ ará Asiria lọ, ó sì ránṣẹ́ sí ọba ńlá náà fún ìrànlọ́wọ́. Ṣùgbọ́n kò le è wò ó sàn bẹ́ẹ̀ ni kò le wo ojú egbò rẹ̀ jinná.
“Rĩrĩa Efiraimu oonire ndwari yake, nake Juda akĩona ironda ciake-rĩ, hĩndĩ ĩyo Efiraimu agĩthiĩ kũrĩ Ashuri, na agĩtũmana kũrĩ mũthamaki ũcio mũnene nĩguo amũteithie. Nowe ndangĩhota gũkũhonia, o na kana ahonie ironda ciaku.
14 Nítorí pé, èmi ó dàbí kìnnìún sí Efraimu, bí i kìnnìún ńlá sí ilé Juda. Èmi ó fà wọ́n ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ èmi ó sì lọ; Èmi ó gbé wọn lọ, láìsí ẹni tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀.
Niĩ ngaatuĩka ta mũrũũthi kũrĩ Efiraimu, nduĩke ta mũrũũthi ũrĩ hinya kũrĩ Juda. Ngaamatambuuranga, njooke ndĩthiĩre; ngaamataha, na gũtirĩ mũndũ ũkaamahonokia.
15 Nígbà náà ni èmi ó padà lọ sí ààyè mi títí di ìgbà tí wọn ó fi gbà pé àwọn jẹ̀bi wọn yóò sì wá ojú mi nínú ìpọ́njú wọn, wọn ó fi ìtara wá mi.”
Ningĩ niĩ nĩngacooka gwakwa, nginya rĩrĩa magetĩkĩra mahĩtia mao. Nao nĩmakarongooria ũthiũ wakwa; nao mona mathĩĩna nĩmakanongoria na kĩo.”