< Hosea 5 >

1 “Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yìn àlùfáà! Ẹ fetísílẹ̀ ẹ̀yin ọmọ Israẹli! Ẹ gbọ́, ẹ̀yìn ilé ọba! Ìdájọ́ yìí kàn yín. Ẹ ti jẹ́ ẹ̀bìtì ní Mispa àwọ̀n ti a nà sílẹ̀ lórí Tabori.
Oe thai awh haw, vaihmanaw. Isarel miphunnaw hoi siangpahrang im dawk kaawm e naw, nangmanaw teh lawkceng lah na o awh han. Bangkongtetpawiteh, nangmanaw teh Mizpah mon dawk tangkam lah, Tabor mon dawk patung e tamlawk karap lah na o awh.
2 Àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti gbilẹ̀ nínú ìpànìyàn gbogbo wọn ni èmi ó bá wí,
Satheinaw theinae lahoi yon na pap sak awh dawkvah, kai ni ahnimanaw abuemlah ka yue han.
3 mo mọ ohun gbogbo nípa Efraimu Israẹli kò sì pamọ́ fún mi Efraimu, ní báyìí ó ti ṣe àgbèrè Israẹli sì ti díbàjẹ́.
Ephraim e akong teh ka panue, Isarel hai ka hmalah kâhrawk thai mahoeh. Ephraim nang teh atu roeroe na kâyo. Isarel teh a khin.
4 “Ìṣe wọn kò gbà wọ́n láààyè láti padà sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wọn. Ẹ̀mí àgbèrè wà ni ọkàn wọn, wọn kò sì mọ Olúwa.
Ahnimanaw teh, kâyonae muitha ahnimouh koe ao dawkvah, Cathut panuek awh hoeh.
5 Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí lé wọn; àwọn ọmọ Israẹli, àti Efraimu pàápàá kọsẹ̀ nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Juda náà sì kọsẹ̀ pẹ̀lú wọn.
Isarelnaw e a kâoupnae ni amamouh a pabo teh, Isarel hoi Ephraim teh amamae yon dawk a rawp awh teh, ahnimouh hoi cungtalah Judahnaw hai a rawp han.
6 Nígbà tí wọ́n bá lọ pẹ̀lú agbo ẹran àti ọ̀wọ́ ẹran wọn láti wá Olúwa, wọn kò ní rí i, ó ti yọ ara rẹ̀ kúrò láàrín wọn.
Tuhu, maitohu a hrawi awh teh, Cathut tawng hanelah a cei awh eiteh, hmawt awh mahoeh. Cathut teh ahnimouh hoi a kâhla toe.
7 Wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Olúwa wọ́n sì bí àwọn àjèjì ọmọ. Nísinsin yìí, ọdún oṣù tuntun wọn, ni yóò pa wọn run pẹ̀lú ìpín wọn.
Ahnimanaw teh Cathut koe lawk a kam awh e a raphoe awh toe. Bangkongtetpawiteh, alouke miphunnaw a khe awh toe. Amamouh hoi cungtalah a hnopainaw hai a rawk han.
8 “Fọn fèrè ní Gibeah, kí ẹ sì fun ìpè ní Rama. Ẹ pariwo ogun ní Beti-Afeni; máa wárìrì, ìwọ Benjamini.
Gibeah kho dawk vovit hai thoseh, Ramah kho dawk mongka hai thoseh, kâhruetcuetnae ueng awh. Oe! Benjamin miphun hnuklah kangvawi haw.
9 Efraimu yóò di ahoro ní ọjọ́ ìbáwí láàrín àwọn ẹ̀yà Israẹli, Mo sọ ohun tí ó dájú.
Isarelnaw yuenae tueng nah Ephraim teh kingdi han. Patuen kaawm hane naw hah ka pâpho.
10 Àwọn olórí Juda dàbí àwọn tí í máa yí òkúta ààlà kúrò. Èmi ó tú ìbínú gbígbóná mi lé wọn lórí bí ìkún omi.
Judah siangpahrangnaw teh lawrilung ka puen e taminaw patetlah ao awh. Kai ni ahnimouh koe ka lungkhueknae tui patetlah ka awi han.
11 A ni Efraimu lára, a sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ ní ìdájọ́, nítorí pé, ó pinnu láti tẹ̀lé òrìṣà.
Ephraim teh rektapnae a khang. Lawkcengnae a kâhmo dawkvah, a sung. Bangkongtetpawiteh, ahni ni ama lung lahoi kâpoe e patetlah a sak.
12 Mo dàbí kòkòrò aṣọ sí Efraimu, Mo sì dàbí ìdin ara Juda.
Kai teh Ephraim koe ahri lah, Judah koe patawnae lah ka o han.
13 “Nígbà ti Efraimu ri àìsàn rẹ̀, tí Juda sì rí ojú egbò rẹ̀ ni Efraimu bá tọ ará Asiria lọ, ó sì ránṣẹ́ sí ọba ńlá náà fún ìrànlọ́wọ́. Ṣùgbọ́n kò le è wò ó sàn bẹ́ẹ̀ ni kò le wo ojú egbò rẹ̀ jinná.
Ephraim ni a hmânaw thoseh, Judah ni a patawnae thoseh, a hmu toteh Ephraim teh Assiria koe a cei han. Judah teh Jareb siangpahrang koe a cei han. Hatei, hote siangpahrangnaw ni dam sak thai mahoeh.
14 Nítorí pé, èmi ó dàbí kìnnìún sí Efraimu, bí i kìnnìún ńlá sí ilé Juda. Èmi ó fà wọ́n ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ èmi ó sì lọ; Èmi ó gbé wọn lọ, láìsí ẹni tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀.
Bangkongtetpawiteh, Kai teh Ephraim koe sendek patetlah Judah koe sendek thoundoun lah ka o han. Kai ni ka kei e hoi ka rakoung e teh apinihai na lawm thai mahoeh.
15 Nígbà náà ni èmi ó padà lọ sí ààyè mi títí di ìgbà tí wọn ó fi gbà pé àwọn jẹ̀bi wọn yóò sì wá ojú mi nínú ìpọ́njú wọn, wọn ó fi ìtara wá mi.”
Ahnimanaw ni a yonae a pâpho awh hoehroukrak, kai na tawng awh hoehroukrak kama ka onae koe ka cei vaiteh hawvah ka o han. Runae a kâhmo awh toteh kai na tawng awh han.

< Hosea 5 >