< Hosea 4 >

1 Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọmọ Israẹli, nítorí pé Olúwa fi ẹ̀sùn kan ẹ̀yin tí ń gbé ní ilẹ̀ náà. “Kò sí ìwà òtítọ́, kò sí ìfẹ́, Kò sí ìmọ̀ Ọlọ́run ní ilẹ̀ náà,
Pǝrwǝrdigarning sɵzini anglanglar, i Israil baliliri; qünki Pǝrwǝrdigarning zeminda turuwatⱪanlar bilǝn ⱪilidiƣan dǝwasi bar; qünki zeminda ⱨeq ⱨǝⱪiⱪǝt, ⱨeq meⱨribanliⱪ, Hudani ⱨeq bilix-tonux yoⱪtur;
2 àfi èpè, irọ́ pípa àti ìpànìyàn olè jíjà àti panṣágà. Wọ́n rú gbogbo òfin, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sì ń gorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀.
Ⱪarƣax-tillax, yalƣanqiliⱪ, ⱪatilliⱪ, oƣriliⱪ, zinahorluⱪ — bular zeminda yamrap kǝtti; ⱪan üstigǝ ⱪan tɵkülidu.
3 Nítorí èyí, ilẹ̀ náà ń ṣọ̀fọ̀, gbogbo olùgbé ibẹ̀ sì ń ṣòfò dànù. Ẹranko igbó àti ẹyẹ ojú ọ̀run àti ẹja inú omi ló ń kú.
Mana xu sǝwǝbtin zemin matǝm tutidu, uningda turuwatⱪanlarning ⱨǝmmisi jüdǝp ketidu; ular daladiki ⱨaywanlar ⱨǝm asmandiki uqar-ⱪanatlar bilǝn billǝ jüdǝp ketidu; bǝrⱨǝⱪ, dengizdiki beliⱪlarmu yǝp ketilidu.
4 “Ṣùgbọ́n kí ẹnikẹ́ni má ṣe mú ẹ̀sùn wá, kí ẹnìkan má sì ṣe fi ẹ̀sùn kan ẹnìkejì nítorí àwọn ènìyàn rẹ̀ dàbí àwọn ti ń fi ẹ̀sùn kan àlùfáà.
Əmdi ⱨeqkim dǝwa ⱪilixmisun, ⱨeqkim ǝyiblǝxmisun; qünki Mening dǝwayim dǝl sǝn bilǝn, i kaⱨin!
5 Ẹ ń ṣubú lọ́sàn án àti lóru àwọn wòlíì yín sì ń ṣubú pẹ̀lú yín. Èmi ó pa ìyá rẹ run,
Sǝn kündüzdǝ putlixip yiⱪilisǝn; pǝyƣǝmbǝrmu sǝn bilǝn keqidǝ tǝng putlixip yiⱪilidu; wǝ Mǝn anangni ⱨalak ⱪilimǝn.
6 àwọn ènìyàn mi ń ṣègbé nítorí pé wọn kò ní ìmọ̀. “Nítorí pé ẹ ti kọ ìmọ̀ sílẹ̀. Èmi náà kọ̀ yín ní àlùfáà mi; nítorí pé ẹ ti kọ òfin Ọlọ́run yín sílẹ̀, Èmi náà yóò gbàgbé àwọn ọmọ yín.
Mening hǝlⱪim bilimsizliktin ⱨalak ⱪilindi; wǝ sǝnmu bilimni qǝtkǝ ⱪaⱪⱪanikǝnsǝn, Mǝnmu seni qǝtkǝ ⱪaⱪimǝnki, sǝn Manga yǝnǝ ⱨeq kaⱨin bolmaysǝn; Hudayingning ⱪanun-kɵrsǝtmisini untuƣanliⱪing tüpǝylidin, Mǝnmu sening baliliringni untuymǝn.
7 Bí àwọn àlùfáà ṣe ń pọ̀ sí i bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń dẹ́ṣẹ̀ sí mi. Wọ́n yí ògo mi padà sí ohun ìtìjú
Ular kɵpǝygǝnseri, Manga ⱪarxi kɵp gunaⱨ sadir ⱪildi; Mǝn ularning xan-xǝripini xǝrmǝndiqilikkǝ aylanduruwetimǝn.
8 wọ́n ń jẹun nípa ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi, wọ́n sì ń gbádùn nínú ìwà búburú wọn.
Ular hǝlⱪimning gunaⱨini yǝydiƣan bolƣaqⱪa, Ularning jeni [hǝlⱪimning] ⱪǝbiⱨlikigǝ intizar bolidu.
9 Yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe rí náà ni àwọn àlùfáà rí. Èmi ó jẹ gbogbo wọn ní yà nítorí ọ̀nà wọn. Èmi ó sì san án fún wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn.
Wǝ hǝlⱪim ⱪandaⱪ bolsa, kaⱨinlarmu xundaⱪ bolidu; Mǝn [kaⱨinlarning] tutⱪan yollirini ɵz üstigǝ qüxürimǝn, ɵz ⱪilmixlirini bexiƣa ⱪayturimǝn.
10 “Wọn ó máa jẹun ṣùgbọ́n wọn kò ní yó; wọn ó ṣe àgbèrè ṣùgbọ́n, wọn kò ni pọ̀ sí i, nítorí pé wọ́n ti kọ Olúwa sílẹ̀, wọ́n sì ti fi ara wọn
Ular yǝydu, biraⱪ toymaydu, Ular paⱨixilik ⱪilidu, biraⱪ ⱨeq kɵpǝymǝydu; Qünki ular Pǝrwǝrdigarni tingxaxni taxlap kǝtti,
11 fún àgbèrè; wọ́n fi ara wọn fún wáìnì àtijọ́, àti tuntun èyí tó gba òye àwọn ènìyàn mi sọnù.
Ɵzlirini paⱨixilik, xarab wǝ yengi xarabⱪa beƣixlidi; Bu ixlar adǝmning ǝⱪil-zeⱨnini bulap ketidu.
12 Wọ́n ń gba ìmọ̀ràn lọ́wọ́ ère igi ọ̀pá igi sì ń dá wọn lóhùn. Ẹ̀mí àgbèrè ti mú wọn ṣìnà wọ́n sì jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run wọn.
Hǝlⱪim ɵz tayiⱪidin yolyoruⱪ soraydu, Ularning ⱨasisi ularƣa yol kɵrsitǝrmix! Qünki paⱨixilikning roⱨi ularni azduridu, Ular Hudasining ⱨimayisi astidin paⱨixilikkǝ qiⱪip,
13 Wọ́n ń rú ẹbọ lórí àwọn òkè ńlá, wọ́n sì ń sun ọrẹ tùràrí lórí àwọn òkè kékeré, lábẹ́ igi óákù, àti igi Poplari àti igi ẹlimuati onírúurú igi tí ìbòjú rẹ̀ dára. Nítorí náà àwọn ọmọbìnrin yín yóò ṣe àgbèrè àti àwọn àfẹ́sọ́nà yín yóò ṣe àgbèrè.
Taƣ qoⱪⱪilirida ⱪurbanliⱪ ⱪilidu, Dɵng-egizliklǝrdǝ, xundaⱪla sayisi yahxi bolƣaqⱪa dub wǝ terǝk wǝ ⱪariyaƣaqlar astidimu isriⱪ salidu; Xunga ⱪizliringlar paⱨixilik, kelinliringlarmu zinahorluⱪ ⱪilidu.
14 “Èmi kò ní jẹ àwọn ọmọbìnrin yín ní yà nígbà tí wọ́n bá ṣe àgbèrè tàbí àwọn àfẹ́sọ́nà ọmọ yín, nígbà tí wọ́n bá ṣe àgbèrè nítorí pé àwọn ọkùnrin pàápàá ń bá alágbèrè kẹ́gbẹ́. Wọ́n sì ń rú ẹbọ pẹ̀lú àwọn alágbèrè ojúbọ òrìṣà. Nítorí náà, ènìyàn tí kò bá ní òye yóò parun!
Mǝn ⱪizliringlarni paⱨixilikliri üqün, Yaki kelinliringlarni zinahorluⱪliri üqün jazalimaymǝn; Qünki [atiliri] ɵzlirimu paⱨixilǝr bilǝn sirtⱪa qiⱪidu, «Buthana paⱨixǝ»liri bilǝn billǝ ⱪurbanliⱪ ⱪilidu; Xuning bilǝn yorutulmiƣan bir hǝlⱪ yiⱪitilidu.
15 “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o ṣe àgbèrè ìwọ Israẹli, ìdájọ́ yìí wà fún un yín. Ẹ má ṣe jẹ́ kí Juda di ẹlẹ́bi. “Ẹ má ṣe lọ sí Gilgali. Ẹ má sì ṣe gòkè lọ sí Beti-Afeni ẹ má sì búra pé, ‘Bí Olúwa ti wà láààyè nítòótọ́!’
Sǝn, i Israil, paⱨixilik ⱪilixing bilǝn, Yǝⱨuda gunaⱨⱪa qetilip ⱪalmisun! Nǝ Gilgalƣa kǝlmǝnglar, nǝ «Bǝyt-Awǝn»gǝ qiⱪmanglar, Nǝ «Pǝrwǝrdigarning ⱨayati bilǝn!» dǝp ⱪǝsǝm ⱪilmanglar.
16 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe agídí bí alágídí ọmọ màlúù. Báwo wá ni Olúwa ṣe fẹ́ bọ́ wọn bí àgùntàn ní pápá oko tútù?
Qünki tǝrsa bir ⱪisir inǝktǝk, Israil tǝrsaliⱪ ⱪilidu; Pǝrwǝrdigar ⱪandaⱪmu pahlanni baⱪⱪandǝk, ularni kǝng bir yaylaⱪta ozuⱪlandursun?
17 Efraimu ti darapọ̀ mọ́ òrìṣà, ẹ fi sílẹ̀!
Əfraim butlarƣa qaplaxti; Uning bilǝn ⱨeqkimning kari bolmisun!
18 Bí ohun mímu wọn bá tilẹ̀ tán, wọ́n tún tẹ̀síwájú nínú àgbèrè. Àwọn olórí wọn fẹ́ràn ohun ìtìjú ju ohun ìyìn lọ.
Ularning xarabi tügixi bilǝnla, Ular ɵzlirini paⱨixilikkǝ beƣixlaydu; Ularning esilzadiliri nomussizliⱪⱪa ǝsǝbiylǝrqǝ mǝptun boldi.
19 Ìjì ni yóò gbá wọn lọ. Gbogbo ìrúbọ wọn yóò sì kó ìtìjú bá wọn.
Bir xamal-roⱨ ularni ⱪanatliri iqigǝ oriwaldi, Ular ⱪurbanliⱪliri tüpǝylidin iza-aⱨanǝtkǝ ⱪalidu.

< Hosea 4 >