< Hosea 4 >

1 Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọmọ Israẹli, nítorí pé Olúwa fi ẹ̀sùn kan ẹ̀yin tí ń gbé ní ilẹ̀ náà. “Kò sí ìwà òtítọ́, kò sí ìfẹ́, Kò sí ìmọ̀ Ọlọ́run ní ilẹ̀ náà,
Perwerdigarning sözini anglanglar, i Israil baliliri; chünki Perwerdigarning zéminda turuwatqanlar bilen qilidighan dewasi bar; chünki zéminda héch heqiqet, héch méhribanliq, Xudani héch bilish-tonush yoqtur;
2 àfi èpè, irọ́ pípa àti ìpànìyàn olè jíjà àti panṣágà. Wọ́n rú gbogbo òfin, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sì ń gorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀.
Qarghash-tillash, yalghanchiliq, qatilliq, oghriliq, zinaxorluq — bular zéminda yamrap ketti; qan üstige qan tökülidu.
3 Nítorí èyí, ilẹ̀ náà ń ṣọ̀fọ̀, gbogbo olùgbé ibẹ̀ sì ń ṣòfò dànù. Ẹranko igbó àti ẹyẹ ojú ọ̀run àti ẹja inú omi ló ń kú.
Mana shu sewebtin zémin matem tutidu, uningda turuwatqanlarning hemmisi jüdep kétidu; ular daladiki haywanlar hem asmandiki uchar-qanatlar bilen bille jüdep kétidu; berheq, déngizdiki béliqlarmu yep kétilidu.
4 “Ṣùgbọ́n kí ẹnikẹ́ni má ṣe mú ẹ̀sùn wá, kí ẹnìkan má sì ṣe fi ẹ̀sùn kan ẹnìkejì nítorí àwọn ènìyàn rẹ̀ dàbí àwọn ti ń fi ẹ̀sùn kan àlùfáà.
Emdi héchkim dewa qilishmisun, héchkim eyibleshmisun; chünki Méning dewayim del sen bilen, i kahin!
5 Ẹ ń ṣubú lọ́sàn án àti lóru àwọn wòlíì yín sì ń ṣubú pẹ̀lú yín. Èmi ó pa ìyá rẹ run,
Sen kündüzde putliship yiqilisen; peyghembermu sen bilen kéchide teng putliship yiqilidu; we Men anangni halak qilimen.
6 àwọn ènìyàn mi ń ṣègbé nítorí pé wọn kò ní ìmọ̀. “Nítorí pé ẹ ti kọ ìmọ̀ sílẹ̀. Èmi náà kọ̀ yín ní àlùfáà mi; nítorí pé ẹ ti kọ òfin Ọlọ́run yín sílẹ̀, Èmi náà yóò gbàgbé àwọn ọmọ yín.
Méning xelqim bilimsizliktin halak qilindi; we senmu bilimni chetke qaqqanikensen, Menmu séni chetke qaqimenki, sen Manga yene héch kahin bolmaysen; Xudayingning qanun-körsetmisini untughanliqing tüpeylidin, Menmu séning baliliringni untuymen.
7 Bí àwọn àlùfáà ṣe ń pọ̀ sí i bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń dẹ́ṣẹ̀ sí mi. Wọ́n yí ògo mi padà sí ohun ìtìjú
Ular köpeygenséri, Manga qarshi köp gunah sadir qildi; Men ularning shan-sheripini shermendichilikke aylanduruwétimen.
8 wọ́n ń jẹun nípa ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi, wọ́n sì ń gbádùn nínú ìwà búburú wọn.
Ular xelqimning gunahini yeydighan bolghachqa, Ularning jéni [xelqimning] qebihlikige intizar bolidu.
9 Yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe rí náà ni àwọn àlùfáà rí. Èmi ó jẹ gbogbo wọn ní yà nítorí ọ̀nà wọn. Èmi ó sì san án fún wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn.
We xelqim qandaq bolsa, kahinlarmu shundaq bolidu; Men [kahinlarning] tutqan yollirini öz üstige chüshürimen, öz qilmishlirini béshigha qayturimen.
10 “Wọn ó máa jẹun ṣùgbọ́n wọn kò ní yó; wọn ó ṣe àgbèrè ṣùgbọ́n, wọn kò ni pọ̀ sí i, nítorí pé wọ́n ti kọ Olúwa sílẹ̀, wọ́n sì ti fi ara wọn
Ular yeydu, biraq toymaydu, Ular pahishilik qilidu, biraq héch köpeymeydu; Chünki ular Perwerdigarni tingshashni tashlap ketti,
11 fún àgbèrè; wọ́n fi ara wọn fún wáìnì àtijọ́, àti tuntun èyí tó gba òye àwọn ènìyàn mi sọnù.
Özlirini pahishilik, sharab we yéngi sharabqa béghishlidi; Bu ishlar ademning eqil-zéhnini bulap kétidu.
12 Wọ́n ń gba ìmọ̀ràn lọ́wọ́ ère igi ọ̀pá igi sì ń dá wọn lóhùn. Ẹ̀mí àgbèrè ti mú wọn ṣìnà wọ́n sì jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run wọn.
Xelqim öz tayiqidin yolyoruq soraydu, Ularning hasisi ulargha yol körsitermish! Chünki pahishilikning rohi ularni azduridu, Ular Xudasining himayisi astidin pahishilikke chiqip,
13 Wọ́n ń rú ẹbọ lórí àwọn òkè ńlá, wọ́n sì ń sun ọrẹ tùràrí lórí àwọn òkè kékeré, lábẹ́ igi óákù, àti igi Poplari àti igi ẹlimuati onírúurú igi tí ìbòjú rẹ̀ dára. Nítorí náà àwọn ọmọbìnrin yín yóò ṣe àgbèrè àti àwọn àfẹ́sọ́nà yín yóò ṣe àgbèrè.
Tagh choqqilirida qurbanliq qilidu, Döng-égizliklerde, shundaqla sayisi yaxshi bolghachqa dub we térek we qariyaghachlar astidimu isriq salidu; Shunga qizliringlar pahishilik, kélinliringlarmu zinaxorluq qilidu.
14 “Èmi kò ní jẹ àwọn ọmọbìnrin yín ní yà nígbà tí wọ́n bá ṣe àgbèrè tàbí àwọn àfẹ́sọ́nà ọmọ yín, nígbà tí wọ́n bá ṣe àgbèrè nítorí pé àwọn ọkùnrin pàápàá ń bá alágbèrè kẹ́gbẹ́. Wọ́n sì ń rú ẹbọ pẹ̀lú àwọn alágbèrè ojúbọ òrìṣà. Nítorí náà, ènìyàn tí kò bá ní òye yóò parun!
Men qizliringlarni pahishilikliri üchün, Yaki kélinliringlarni zinaxorluqliri üchün jazalimaymen; Chünki [atiliri] özlirimu pahishiler bilen sirtqa chiqidu, «Butxana pahishe»liri bilen bille qurbanliq qilidu; Shuning bilen yorutulmighan bir xelq yiqitilidu.
15 “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o ṣe àgbèrè ìwọ Israẹli, ìdájọ́ yìí wà fún un yín. Ẹ má ṣe jẹ́ kí Juda di ẹlẹ́bi. “Ẹ má ṣe lọ sí Gilgali. Ẹ má sì ṣe gòkè lọ sí Beti-Afeni ẹ má sì búra pé, ‘Bí Olúwa ti wà láààyè nítòótọ́!’
Sen, i Israil, pahishilik qilishing bilen, Yehuda gunahqa chétilip qalmisun! Ne Gilgalgha kelmenglar, ne «Beyt-Awen»ge chiqmanglar, Ne «Perwerdigarning hayati bilen!» dep qesem qilmanglar.
16 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe agídí bí alágídí ọmọ màlúù. Báwo wá ni Olúwa ṣe fẹ́ bọ́ wọn bí àgùntàn ní pápá oko tútù?
Chünki tersa bir qisir inektek, Israil tersaliq qilidu; Perwerdigar qandaqmu paxlanni baqqandek, ularni keng bir yaylaqta ozuqlandursun?
17 Efraimu ti darapọ̀ mọ́ òrìṣà, ẹ fi sílẹ̀!
Efraim butlargha chaplashti; Uning bilen héchkimning kari bolmisun!
18 Bí ohun mímu wọn bá tilẹ̀ tán, wọ́n tún tẹ̀síwájú nínú àgbèrè. Àwọn olórí wọn fẹ́ràn ohun ìtìjú ju ohun ìyìn lọ.
Ularning sharabi tügishi bilenla, Ular özlirini pahishilikke béghishlaydu; Ularning ésilzadiliri nomussizliqqa esebiylerche meptun boldi.
19 Ìjì ni yóò gbá wọn lọ. Gbogbo ìrúbọ wọn yóò sì kó ìtìjú bá wọn.
Bir shamal-roh ularni qanatliri ichige oriwaldi, Ular qurbanliqliri tüpeylidin iza-ahanetke qalidu.

< Hosea 4 >