< Hosea 3 >
1 Olúwa sì wí fún mi pé, “Tun lọ fẹ́ obìnrin kan tí í ṣe olùfẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀, àti panṣágà, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Olúwa sì àwọn ọmọ Israẹli tí ń wo àwọn ọlọ́run mìíràn, tí wọ́n sì ń fẹ́ àkàrà èso àjàrà.”
I powiedział do mnie PAN: Idź jeszcze, pokochaj kobietę kochaną [przez] innego – cudzołożnicę, tak jak PAN miłuje synów Izraela, choć oni oglądają się za innymi bogami i kochają bukłaki wina.
2 Nítorí náà, mo sì rà á padà ní ṣékélì fàdákà mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àti homeri kan àti lẹ́tékì barle kan.
Więc kupiłem ją sobie za piętnaście srebrników i za półtora chomera jęczmienia;
3 Mo sì sọ fún un pé, “Ìwọ gbọdọ̀ máa gbé pẹ̀lú mi fún ọjọ́ pípẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe àgbèrè mọ́ tàbí kí o fẹ́ ọkùnrin mìíràn, èmi náà yóò sì gbé pẹ̀lú rẹ.”
I powiedziałem do niej: Pozostaniesz u mnie przez wiele dni. Nie będziesz uprawiała nierządu ani nie będziesz [należała] do [innego] mężczyzny, a ja też [będę] dla ciebie.
4 Nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli yóò wà fún ọjọ́ pípẹ́ láìní ọba tàbí olórí, láìsí ìrúbọ tàbí pẹpẹ mímọ́, láìsí àlùfáà tàbí òrìṣà kankan.
Przez wiele dni bowiem synowie Izraela będą bez króla, bez księcia, bez ofiary, bez posągu, bez efodu i bez terafim.
5 Lẹ́yìn èyí ni àwọn ọmọ Israẹli yóò padà láti wá Olúwa Ọlọ́run wọn àti Dafidi ọba wọn. Wọn yóò sì wá síwájú Olúwa pẹ̀lú ẹ̀rù, wọn ó sì jọ̀wọ́ ara wọn fún Olúwa àti ìbùkún rẹ̀ ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Potem synowie Izraela nawrócą się i będą szukać PANA, swego Boga, i Dawida, swego króla; a w ostatecznych dniach będą się bać PANA i jego dobroci.