< Hosea 3 >

1 Olúwa sì wí fún mi pé, “Tun lọ fẹ́ obìnrin kan tí í ṣe olùfẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀, àti panṣágà, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Olúwa sì àwọn ọmọ Israẹli tí ń wo àwọn ọlọ́run mìíràn, tí wọ́n sì ń fẹ́ àkàrà èso àjàrà.”
Angraeng mah kai khaeah, Kalah sithawnawk khaeah kangqoi ving, Sithaw panoek ai kaminawk mah misurthaih kazaek hoiah sak o ih takaw kakoeh, Israel caanawk khaeah caeh ah loe, Angraeng mah Israel caanawk palung baktih toengah, a tlangai mah palung duek ih, oep kaom ai zaehaih sah nongpata to tlangai ah suem ah, tiah ang naa.
2 Nítorí náà, mo sì rà á padà ní ṣékélì fàdákà mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àti homeri kan àti lẹ́tékì barle kan.
To pongah anih to kaimah hanah sum kanglung shekel hatlai pangato, barli cang noekhaih homer maeto pacoeng, ahap hoiah ka qanh:
3 Mo sì sọ fún un pé, “Ìwọ gbọdọ̀ máa gbé pẹ̀lú mi fún ọjọ́ pípẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe àgbèrè mọ́ tàbí kí o fẹ́ ọkùnrin mìíràn, èmi náà yóò sì gbé pẹ̀lú rẹ.”
to pacoengah kai mah anih khaeah, Nang loe kai taham ah ni na om tih boeh, tangzat zaw hmah lai ah, minawk kalah tlangai doeh tawn hmah laih, kai loe nang hanah ni ka hing toeng han boeh, tiah ka naa.
4 Nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli yóò wà fún ọjọ́ pípẹ́ láìní ọba tàbí olórí, láìsí ìrúbọ tàbí pẹpẹ mímọ́, láìsí àlùfáà tàbí òrìṣà kankan.
Israel caanawk loe siangpahrang tawn ai, ukkung angraeng tawn ai, angbawnhaih om ai, sakcop ih krang tawn ai, kahni tawn ai, teraphim doeh om ai ah ni kasawk ah om o tih.
5 Lẹ́yìn èyí ni àwọn ọmọ Israẹli yóò padà láti wá Olúwa Ọlọ́run wọn àti Dafidi ọba wọn. Wọn yóò sì wá síwájú Olúwa pẹ̀lú ẹ̀rù, wọn ó sì jọ̀wọ́ ara wọn fún Olúwa àti ìbùkún rẹ̀ ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Ani boeng naah, Israel caanawk mah anih hoihhaih to hnuk o moe, angmacae ih Angraeng Sithaw hoi angmacae ih siangpahrang, David to pakrong hanah, Angraeng zithaih hoiah amlaem o let tih.

< Hosea 3 >