< Hosea 3 >

1 Olúwa sì wí fún mi pé, “Tun lọ fẹ́ obìnrin kan tí í ṣe olùfẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀, àti panṣágà, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Olúwa sì àwọn ọmọ Israẹli tí ń wo àwọn ọlọ́run mìíràn, tí wọ́n sì ń fẹ́ àkàrà èso àjàrà.”
Hina Gode da nama amane sia: i, “Dia uda da di baligi fa: le, asili, eno sasagesu dunuma gilisili golasa. Be amo mae dawa: le, di ema asili, bu asigidafa hou olelema. Na fi dunu da sinidigili, ogogosu ‘gode’ ilima fa: no bobogele, ilima hafoga: i waini fage gobele salimusa: gaguli ahoa. Be Na da ilima asigisa. Amo defele, dia baligi fa: su udama asigima.”
2 Nítorí náà, mo sì rà á padà ní ṣékélì fàdákà mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àti homeri kan àti lẹ́tékì barle kan.
Amaiba: le, na da na uda bu bidiga lamusa: , silifa fage15 amola bali150 gilogala: me amo i.
3 Mo sì sọ fún un pé, “Ìwọ gbọdọ̀ máa gbé pẹ̀lú mi fún ọjọ́ pípẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe àgbèrè mọ́ tàbí kí o fẹ́ ọkùnrin mìíràn, èmi náà yóò sì gbé pẹ̀lú rẹ.”
Na da ema amane sia: i, “Di da eso bagohame ouesaloma! Amo esoga, di da dina: da: i bidi hame lamu amola eno dunuma gilisili hame golama: mu. Amola amo esoga, na di bu lamusa: ne ouesalumu.”
4 Nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli yóò wà fún ọjọ́ pípẹ́ láìní ọba tàbí olórí, láìsí ìrúbọ tàbí pẹpẹ mímọ́, láìsí àlùfáà tàbí òrìṣà kankan.
Amo hou defele, Isala: ili dunu da hina bagade hame, amola ouligisu dunu hame gala udigili ouesalumu. Ilia da gobele salasu hou hame, sema gele ganumu hame, loboga hamoi ogogosu ‘gode’ hame gala, amola liligi amoga ilia ba: la: lusu hamosa, amo hame gala, eso bagohame udigili ouesalumu.
5 Lẹ́yìn èyí ni àwọn ọmọ Israẹli yóò padà láti wá Olúwa Ọlọ́run wọn àti Dafidi ọba wọn. Wọn yóò sì wá síwájú Olúwa pẹ̀lú ẹ̀rù, wọn ó sì jọ̀wọ́ ara wọn fún Olúwa àti ìbùkún rẹ̀ ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Be eso da misunu amoga Isala: ili dunu da ilia Hina Godedafa amoma bu sinidigimu. Amola ilia da Da: ibidi egaga fi dunu afae ema sinidigimu. Amasea, ilia da Hina Godema bu beda: iba: le, Ea hahawane dogolegele iasu liligi bu ba: mu.

< Hosea 3 >