< Hosea 2 >

1 “Sọ fún àwọn arákùnrin rẹ, ‘Ènìyàn mi,’ kí o sì wí fún àwọn arábìnrin rẹ ‘Àyànfẹ́ mi.’
Na hmaunawnghanaw hah ka tami telah thoseh, na tawncanunaw hah ka pahren e ka canu telah thoseh bout ka kaw han.
2 “Ẹ bá ìyá yín wí, ẹ bá a wí, nítorí pé kì í ṣe ìyàwó mi, Èmi náà kì í sì í ṣe ọkọ rẹ̀. Jẹ́ kí ó yọ àgbèrè rẹ̀ kúrò lójú rẹ̀ àti àìṣòótọ́ kúrò ní àyà rẹ̀.
Na manu teh dei pouh awh. Ahni teh kaie ka yu nahoeh. Kai haiyah ahnie a vâ nahoeh.
3 Àìṣe bẹ́ẹ̀ èmi yóò tú u sí ìhòhò, Èmi yóò sì gbé e kalẹ̀ bí ọjọ́ tí a bí i. Èmi yóò ṣe ọ́ bí i aṣálẹ̀ ilẹ̀, Èmi yóò sì sọ ọ́ di ìyàngbẹ ilẹ̀ Èmi yóò sì fi òǹgbẹ gbẹ ẹ́.
Kâyonae minhmai padai laipalah kathoute hno roun naseh. Roun hoehpawiteh, a khenae patetlah caici lah thingyei um pak ka tha han. Tui ni a hak takhai e talai patetlah tui ka pakoung vaiteh ka due sak han.
4 Èmi kò ní fi àánú mi hàn sí àwọn ọmọ rẹ̀ nítorí ọmọ àgbèrè ni wọ́n jẹ́.
A canaw haiyah cataca lah ao dawkvah kai ni ka pahren mahoeh.
5 Nítorí ìyá wọn ti hùwà àgbèrè, ó sì lóyún wọn nínú ìtìjú. Ó wí pé, ‘Èmi ó tún tọ́ àwọn àyànfẹ́ mi lẹ́yìn, tó ń fún mi ní oúnjẹ àti omi, ní irun àgùntàn mi àti ọ̀gbọ̀ mi, òróró mi àti ohun mímu mi.’
Ahnimae manu teh, kâyawt e doeh. Ahni ka vawn e napui hai yeirai a po toe. Ahni nihaiyah ka bu, ka tui, ka tumuen, ka tangka, ka satui, nei hane tui ouk na ka poe e kapahrennaw hnuk ka kâbang han a ti.
6 Nítorí náà, èmi ó fi ẹ̀gún dì í lọ́nà, Èmi ó mọ odi yí i ká kí ó má ba à rọ́nà lọ.
Hatdawkvah pâkhing hoi ka kalup han. A tâco thai hoeh nahanlah talung hoi ka tapang sin han.
7 Yóò sáré lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ṣùgbọ́n kò ní bá wọn; yóò wá wọn ṣùgbọ́n kò ní rí wọn. Nígbà náà ni yóò sọ pé, ‘Èmi ó padà sí ọ̀dọ̀ ọkọ mi àkọ́kọ́ nítorí pé ó dára fún mi nígbà náà ju ìsinsin yìí lọ.’
A pahren hah a pâlei ei phat mahoeh. A tawng ei hmawt laipalah ao navah, ka vâ karuem koe doeh bout ka cei han toe ati. Atu e hmuen koe hlak hmaloe e hmuen koe doeh hoe ahawi ati han.
8 Nítorí pé kò tí ì mọ̀ pé èmi ni àti ẹni tó fún un ní ọkà, ọtí wáìnì tuntun àti òróró ẹni tí ó fún un ní fàdákà àti wúrà lọ́pọ̀lọ́pọ̀, èyí tí wọ́n lò fún Baali.
Cang, misur, satuinaw hoi Baal bawknae sui hoi ngun hai moi ka poe eiteh, Kai na pahnim awh.
9 “Nítorí náà, èmi yóò mú ọkà mi kúrò nígbà tó bá pọ́n, èmi yóò sì mú wáìnì mi kúrò ní àsìkò rẹ̀. Èmi yóò sì gba irun àgùntàn àti ọ̀gbọ̀ mi padà ti mo ti fi fún un láti bo ìhòhò rẹ̀.
Hatdawkvah canga tue nah cakang, misurtui kasu tue nah misurtui, ka poe mahoeh. Kaie tumuen hoi ngun, a caicinae ramuknae hah ka bankhai han.
10 Èmi yóò sì fi ìwà ìtìjú rẹ̀ hàn lójú àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ kò sí ẹni tí yóò gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ mi,
Atu roeroe a pahrennaw koe a khohna e ka rading pouh vaiteh, yeiraipo sak han. Apinihai ka kut dawk hoi hlout sak thai mahoeh.
11 Èmi yóò mú gbogbo ayọ̀ rẹ̀ wá sí òpin: àjọ̀dún ọdọọdún rẹ̀, oṣù tuntun rẹ̀, ọjọ́ ìsinmi, àti gbogbo àwọn àjọ̀dún tí a yàn.
A nawmnae, pawitonae, thaparei hnin, sabbath hnin, tamimaya kamkhueng e pueng ka pout sak han.
12 Èmi yóò pa àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ run, èyí tí ó pè ní èrè rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, Èmi yóò sọ wọ́n di igbó, àwọn ẹranko búburú yóò sì jẹ́ wọn run.
Het hateh, ka pahren ni na poe e poehno ati e misurnaw, thaibunglungnaw lungpalueng lah ka ta vaiteh, ratu lah ka sak han, hahoi sarangnaw ni a ca awh han.
13 Èmi yóò bẹ̀ ọjọ́ Baalimu wò ní ara rẹ̀ nínú èyí tó ń fi tùràrí jóná fún Baali; tí ó fi òrùka etí àti ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀, ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀ọ́, tó sì tẹ̀lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lọ. Ṣùgbọ́n èmi ni òun gbàgbé,” ni Olúwa wí.
Baal cathutnaw koe hmuitui hmai a sawi awh teh, hnongpacap hoi dingyin a awi awh teh, a pahren hnuk a kâbang awh teh, Kai na pahnim awh dawkvah, Baal cathutnaw e tueng dawk e patetlah moipathung han telah Cathut ni a ti.
14 “Nítorí náà, èmi yóò tàn án, Èmi ó sì mú u lọ sí ilẹ̀ aṣálẹ̀, Èmi ó fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ bá a sọ̀rọ̀
Hatei, ahni hah bout ka pasawt han. Kahrawng lahoi a ceikhai awh nakunghai, pasawtnae lawk hoi ka dei pouh awh han.
15 Níbẹ̀ ni èmi yóò ti dá ọgbà àjàrà rẹ̀ padà fún un, Èmi yóò fi àfonífojì Akori ṣe ìlẹ̀kùn ìrètí fún un. Yóò sì kọrin níbẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbà èwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbà tó kúrò ní Ejibiti.
Hote hmuen koe misur takha hai thoseh, Akhor tanghling koe ngaihawinae takhang hai thoseh ka sak pouh han. A camo nah Izip ram hoi a tâconae la a sak awh e patetlah namran lah a pha awh toteh, la a sak awh han.
16 “Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò pè mí ní ‘ọkọ mi’; ìwọ kò sì ní pè mí ní ‘olúwa à mi mọ́,’ ni Olúwa wí.
BAWIPA ni a dei e teh, hatnae tueng dawk nang ni kai hah Bawipa telah na kaw mahoeh, ka vâ telah na kaw han.
17 Èmi yóò mú orúkọ, àwọn òrìṣà Baali kúrò lẹ́nu rẹ̀; ìwọ kò sì ní rí orúkọ òrìṣà Baali pè mọ́.
Baal e min roeroe heh nangmae pahni dawk hoi takhoe vaiteh, a min hah dei lah rawraw bout dei mahoeh toe.
18 Ní ọjọ́ náà, èmi yóò ṣe májẹ̀mú fún wọn àti àwọn ẹranko igbó àti ẹyẹ ojú ọ̀run àti àwọn ẹ̀dá tí ń rìn lórí ilẹ̀. Kí wọn má bà á bẹ̀rù ara wọn mọ́. Ọfà, idà àti ogun jíjà ni èmi ó parun ní ilẹ̀ náà kí gbogbo ènìyàn bá a lè wà ní àìléwu.
Hatnae tueng dawk Kai ni ahnimouh hanlah, kahrawng e sarang, kalvan e tava, talai dawk e sarangnaw hoi na kâhuiko vaiteh, licung, tahloi, senehmaicanaw, talai dawk hoi ka takhoe han. Lungpuen tâsuenae awm laipalah a i awh han.
19 Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi títí láé; Èmi ó fẹ́ ọ ní ìwà òdodo àti òtítọ́, ní ìfẹ́ àti àánú.
Nang teh, ka yu lah pou na o han toe. Lannae, kamsoum e, ka kuep e lungmanae hoi nang teh kama hanelah na la han toe.
20 Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi ní òtítọ́ ìwọ yóò sì mọ Olúwa.
Ka lawkkam ka tarawi vaiteh na la han, nang ni Cathut na panue han.
21 “Èmi yóò sì dáhùn ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí; “Èmi yóò dá àwọn ọ̀run lóhùn àwọn ọ̀run yóò sì dá ilẹ̀ lóhùn;
Bawipa ni telah ati, hatnae tueng dawk ratoumnae Kai ni na thai pouh han. Kalvan lawk ka thai pouh vai teh, ahni ni talai lawk a thai pouh awh han.
22 ilẹ̀ náà yóò sì dá ọkà, wáìnì tuntun àti òróró lóhùn Gbogbo wọn ó sì dá Jesreeli lóhùn.
Talai ni hai cakang, misurtui, satui, naw e lawk a thai vaiteh, ahnimouh ni hai Jezreel e lawk a thai awh han.
23 Èmi ó sì gbìn ín fún ara mi lórí ilẹ̀ náà, Èmi yóò ṣàánú fún ẹni tí kò tì í ri ‘Àánú gbà.’ Èmi yóò sọ fún àwọn tí ‘Kì í ṣe ènìyàn mi pé,’ ‘Ẹ̀yin ni ènìyàn mi’; àwọn náà yóò sì wí pé, ‘Ìwọ ni Ọlọ́run mi.’”
Hote napui hah cati patetlah talai dawk kama hane ka patue han. Ka pahren hoeh e napui hah ka pahren han. Ka tami hoeh e koe ka tami ka ti pouh han. Ahnimouh ni hai nang teh kaimae Cathut doeh na ti pouh awh. han.

< Hosea 2 >