< Hosea 13 >

1 Nígbà ti Efraimu bá ń sọ̀rọ̀, àwọn ènìyàn máa ń wárìrì, a gbé e ga ní Israẹli ṣùgbọ́n ó jẹ̀bi ẹ̀sùn pé ó ń sin òrìṣà Baali, ó sì kú.
Naar Efraim talte, var der Skræk, han ophøjede sig i Israel; men han blev skyldig ved Baal og døde.
2 Báyìí, wọ́n ń dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀; wọn fi fàdákà ṣe ère òrìṣà fúnra wọn; ère tí a fi ọgbọ́n dá àrà sí, gbogbo wọn jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ oníṣọ̀nà. Wọn ń sọ nípa àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Pé, “Jẹ́ kí àwọn ènìyàn tí ń rú ẹbọ fi ẹnu, ko àwọn ẹgbọrọ màlúù ni ẹnu.”
Og nu blive de ved at synde og gøre sig støbte Billeder af deres Sølv, Afguder efter deres Forstand, alt sammen Kunstneres Værk; om dem sige de, nemlig de Mennesker, som ofre, at de skulle kysse Kalve.
3 Nítorí náà wọn yóò dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀, bí ìrì òwúrọ̀ kùtùkùtù tó máa ń parẹ́, bí i èèpo ìyẹ̀fun tí afẹ́fẹ́ gbé láti ibi ìpakà bí èéfín tó rú jáde gba ojú fèrèsé.
Derfor skulle de vorde som en Sky om Morgenen og som Duggen, der aarle gaar bort, som Avner, der vejres bort fra Tærskepladsen, og som Røg ud af et Vindue.
4 “Ṣùgbọ́n Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ẹni tó mú ọ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá. Ìwọ̀ kì yóò sì mọ ọlọ́run mìíràn àfi èmi kò sí olùgbàlà mìíràn lẹ́yìn mi.
Men jeg er Herren din Gud fra Ægyptens Land af, og en Gud uden mig kender du ikke, og en Frelser uden mig er der ikke.
5 Mo ṣe ìtọ́jú rẹ ní aginjù, ní ilẹ̀ tí ó gbẹ tí kò ní omi.
Jeg, jeg kendte dig i Ørken, i det tørre Land.
6 Wọn ni ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí mo fún wọn ní oúnjẹ, Nígbà tí wọ́n ní ìtẹ́lọ́rùn tan wọ́n di agbéraga. Nígbà náà ni wọ́n sì gbàgbé mi.
Som de kom paa Græsgang, bleve de mætte, de bleve mætte, og deres Hjerte ophøjede sig; derfor glemte de mig.
7 Nítorí náà, Èmi yóò dìde sí wọn bí i kìnnìún, Èmi yóò fi ara pamọ́ dè wọ́n lọ́nà bí i ẹkùn.
Og jeg blev dem som en Løve, som en Parder lurer jeg paa Vejen.
8 Beari igbó tí a já ọmọ rẹ̀ gbà, Èmi yóò bá wọn jà bí? Èmi yóò sì fà wọ́n ya bí ìgbà tí ẹkùn bá fa ara wọn ya bi ẹranko búburú ni èmi yóò fa wọn ya.
Jeg vil anfalde dem som en Bjørn, der er berøvet sine Unger, og vil sønderrive deres Hjertes Lukke, og jeg vil fortære dem der som en Løvinde, Markens Dyr skulle sønderslide dem.
9 “A ti pa ọ́ run, ìwọ Israẹli, nítorí pé ìwọ lòdì sí mi, ìwọ lòdì sí olùrànlọ́wọ́ rẹ.
Det var din Fordærvelse, Israel! at du var imod mig, imod din Hjælp.
10 Níbo ni ọba rẹ gbé wà nísinsin yìí kí ó bá à le gbà ọ là? Níbo ni àwọn olórí ìlú yín wà, àwọn tí ẹ sọ pé, ‘Fún wa ní ọba àti ọmọ-aládé’?
Hvor er nu din Konge, at han kan frelse dig i alle dine Stæder? og dine Dommere, om hvilke du sagde: Giv mig Konge og Fyrster?
11 Nítorí èyí nínú ìbínú mi ni mo fún un yín ní ọba, nínú ìbínú gbígbóná mi, mo sì mú un kúrò.
Jeg giver dig en Konge i min Vrede og tager ham bort i min Harme.
12 Ẹ̀bi Efraimu ni a tí ko jọ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ wà nínú àkọsílẹ̀.
Efraims Misgerning er sammenbunden, hans Synd er gemt.
13 Ìrora bí obìnrin tó fẹ́ bímọ ti dé bá a, ṣùgbọ́n ó jẹ́ ọmọ tí kò lọ́gbọ́n, nígbà tí àsìkò tó, ó kọ̀ láti jáde síta láti inú.
Smerter skulle komme paa ham som paa Kvinden, der føder; han er ikke en viis Søn, thi han burde ikke en Tid blive staaende i Fødselens Gennembrud.
14 “Èmi yóò rà wọ́n padà kúrò lọ́wọ́ agbára isà òkú. Èmi yóò rà wọ́n padà lọ́wọ́ ikú, ikú, àjàkálẹ̀-ààrùn rẹ dà? Isà òkú, ìparun rẹ dà? “Èmi kò ní ṣàánú mọ́. (Sheol h7585)
Af Dødsrigets Vold vil jeg forløse dem, fra Døden vil jeg genløse dem; Død! hvor er din Pest? Dødsrige! hvor er din ødelæggende Magt? Fortrydelse er skjult for mine Øjne. (Sheol h7585)
15 Bí ó tilẹ̀ gbilẹ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀ afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn láti ọ̀dọ̀ Olúwa yóò wá, yóò fẹ́ wá láti inú aginjù orísun omi rẹ̀ yóò gbẹ kànga rẹ̀ yóò gbẹ pẹ̀lú olè yóò fọ́ ilé ẹrù àti gbogbo ilé ìṣúra rẹ̀.
Thi han skal bære Frugt iblandt Brødre; dog skal der komme et Østenvejr, et Herrens Vejr, som drager op fra Ørken, og hans Væld skal udtørres og hans Kilde blive tør; det skal røve Skatten af alle kostelige Kar.
16 Ará Samaria gbọdọ̀ ru ẹ̀bi wọn, nítorí pé wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí Ọlọ́run wọn. Wọn ó ti ipa idà ṣubú; a ó fọ́ àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀, a ó sì la àwọn aboyún wọn nínú.”
Samaria skal bøde, thi den har været genstridig imod Gud; de skulle falde ved Sværdet, deres spæde Børn skulle knuses og deres frugtsommelige Kvinder sønderrives.

< Hosea 13 >