< Hosea 11 >
1 “Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀, mo sì pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti wá.
“Rĩrĩa Isiraeli aarĩ kaana-rĩ, nĩndamwendete, ngĩgĩĩta mũrũ ũcio wakwa oime bũrũri wa Misiri.
2 Bí a ti ń pe wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń sá kúrò lọ́dọ̀ mi, wọn rú ẹbọ sí Baali, wọn sì fi tùràrí jóná sí ère fínfín.
No o ũrĩa ndaakĩragĩrĩria gwĩta Isiraeli, noguo maakĩragĩrĩria kũnjũrĩra. Nao makĩrutĩra Baali magongona, na magĩcinĩra mĩhianano ũbumba.
3 Lóòtítọ́ mo kọ́ Efraimu pẹ̀lú ní ìrìn mo di wọ́n mú ní apá, ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ pé mo ti mú wọn láradá.
Niĩ nĩ niĩ ndaarutire andũ a Efiraimu gwĩtwara na magũrũ, ndĩmanyiitĩte moko; no matiigana kũmenya atĩ nĩ niĩ ndamahonagia.
4 Mo fi okùn ènìyàn fà wọ́n àti ìdè ìfẹ́. Mo mú àjàgà kúrò ni ọrùn wọn, Mo sì fi ara balẹ̀ fún wọn ni oúnjẹ.
Nĩndamatongoragia na mĩkanda ya ũtugi wa ũmũndũ, ngamaguucĩrĩria na mĩhĩndo ya wendo; ngĩmaruta icooki ngingo, na ngĩinamĩrĩra kũmahe irio.
5 “Ṣé wọn ò wá ní padà sí Ejibiti bí. Ṣé Asiria kò sì ní jẹ ọba lé wọn lórí bí nítorí pé wọ́n kọ̀ jálẹ̀ láti ronúpìwàdà?
“Githĩ matigagĩcooka o kũu bũrũri wa Misiri, o na githĩ matigaathwo nĩ Ashuri, tondũ nĩmaregete kwĩrira, manjookerere?
6 Idà yóò kọ mọ̀nà ní gbogbo ìlú wọn yóò si bá gbogbo irin ẹnu odi ìlú wọn jẹ́ yóò sì fi òpin sí gbogbo èrò wọn.
Hiũ cia njora ikaahenũkaga matũũra-inĩ mao manene, ikaananga mĩgĩĩko ya ihingo ciao, na ikinyie mĩbango yao mũthia.
7 Àwọn ènìyàn mi ti pinnu láti pẹ̀yìndà kúrò lọ́dọ̀ mi bí wọ́n tilẹ̀ pè wọ́n sọ́dọ̀ Ọ̀gá-ògo jùlọ, kò ní gbé wọn ga rárá.
Andũ akwa nĩmatuĩte itua maahuutatĩre. O na mangĩgaakaĩra Ũrĩa-ũrĩ-Igũrũ-Mũno-rĩ, ndakamatũgĩria o na atĩa.
8 “Báwo ni èmi ó ṣe fi ọ́ sílẹ̀, Efraimu? Báwo ni èmi ó ṣe yọ̀ǹda rẹ̀, Israẹli? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Adma? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Seboimu? Ọkàn mi yípadà nínú mi àánú mi sì ru sókè.
“Ndahota atĩa gũgũtirika, wee Efiraimu? Ndahota atĩa gũkũrekereria, wee Isiraeli? Ndahota atĩa gũtũma ũtuĩke ta Adima? Ndahota atĩa gũgũtua ta Zeboimu? Ngoro yakwa nĩĩreganĩte na ũhoro ũcio, nacio tha ciakwa ciothe nĩciarahũkĩte.
9 Èmi kò ni mú ìbínú gbígbóná mi ṣẹ, tàbí kí èmi wá sọ Efraimu di ahoro. Nítorí pé èmi ni Ọlọ́run, àní, èmi kì í ṣe ènìyàn. Ẹni mímọ́ láàrín yín, Èmi kò ní í wá nínú ìbínú.
Ndikamũkinyĩria marakara makwa mahiũ, o na kana hũgũkĩre Efiraimu ndĩmũniine. Nĩgũkorwo niĩ nĩ niĩ Ngai, ndirĩ mũndũ, Ngai Ũrĩa Mũtheru gatagatĩ-inĩ kanyu. Ndigooka kũrĩ we ndĩ na mangʼũrĩ.
10 Wọn yóò máa tẹ̀lé Olúwa; òun yóò bú ramúramù bí i kìnnìún. Nígbà tó bá bú, àwọn ọmọ rẹ yóò wá ní ìwárìrì láti ìwọ̀-oòrùn.
Nĩmakarũmĩrĩra Jehova; nake nĩakararama ta mũrũũthi. Hĩndĩ ĩrĩa akaararama-rĩ, ciana ciake nĩigooka ikĩinainaga ciumĩte mwena wa ithũĩro.
11 Wọn ó wá pẹ̀lú ẹ̀rù bí i ẹyẹ láti Ejibiti, bí i àdàbà láti Asiria, Èmi ó mú wọn padà sí ilé wọn,” ni Olúwa wí.
Igooka ikĩinainaga ta nyoni ikiuma bũrũri wa Misiri, na ta ndutura ikiuma bũrũri wa Ashuri. Nĩngatũma matũũre mĩciĩ-inĩ yao ene,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
12 Efraimu tí fi irọ́ yí mi ká ilé Israẹli pẹ̀lú ẹ̀tàn. Ṣùgbọ́n Juda sì dúró ṣinṣin pẹ̀lú Ọlọ́run. Ó sì ṣe olóòtítọ́ sí Ẹni mímọ́ Israẹli.
Efiraimu andigiicĩirie na maheeni, nyũmba ya Isiraeli ĩkandigiicĩria na kũheenania. Nake Juda akaremera Ngai, o na agookĩrĩra Ũrĩa Mũtheru mwĩhokeku.