< Hosea 11 >
1 “Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀, mo sì pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti wá.
Nawkta nathuem ah Israel to ka palung, Izip prae thung hoiah ka capa to ka kawk.
2 Bí a ti ń pe wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń sá kúrò lọ́dọ̀ mi, wọn rú ẹbọ sí Baali, wọn sì fi tùràrí jóná sí ère fínfín.
Nihcae to ka kawk naah, nihcae loe kangthla aep ah caeh o: Baalnawk khaeah hmuen tathlanghaih to a sak o moe, krangnawk khaeah hmuihoih a thlaek o.
3 Lóòtítọ́ mo kọ́ Efraimu pẹ̀lú ní ìrìn mo di wọ́n mú ní apá, ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ pé mo ti mú wọn láradá.
Ephraim caeh thaih hanah ka patuk, anih ih ban ah ka patawnh moe, ka hoih; toe kai mah ngan ka tuisak, tito nihcae mah panoek o ai.
4 Mo fi okùn ènìyàn fà wọ́n àti ìdè ìfẹ́. Mo mú àjàgà kúrò ni ọrùn wọn, Mo sì fi ara balẹ̀ fún wọn ni oúnjẹ.
Nihcae to poeknaemhaih hoiah ka zaeh moe, amlunghaih hoiah ka zaeng; kai loe nihcae hanah tahnong ih hnam kakhringh pae kaminawk baktiah ka oh, nihcae to buh ka pacah.
5 “Ṣé wọn ò wá ní padà sí Ejibiti bí. Ṣé Asiria kò sì ní jẹ ọba lé wọn lórí bí nítorí pé wọ́n kọ̀ jálẹ̀ láti ronúpìwàdà?
Nihcae loe dawnpakhuem o ai pongah, anih loe Izip prae ah amlaem mak ai, Assyria kami loe anih ih siangpahrang ah om tih.
6 Idà yóò kọ mọ̀nà ní gbogbo ìlú wọn yóò si bá gbogbo irin ẹnu odi ìlú wọn jẹ́ yóò sì fi òpin sí gbogbo èrò wọn.
Anih ih vangpuinawk thungah sumsen alaekhaih to om tih, angmacae sak atimhaih baktih toengah, a ohhaih ahmuen to amro ueloe, nihcae to amrosak tih.
7 Àwọn ènìyàn mi ti pinnu láti pẹ̀yìndà kúrò lọ́dọ̀ mi bí wọ́n tilẹ̀ pè wọ́n sọ́dọ̀ Ọ̀gá-ògo jùlọ, kò ní gbé wọn ga rárá.
Kai ih kaminawk loe kai hnuk angqoi taak ving hanah poek o: nihcae mah to Kasang Koek, tiah palawk o, toe Anih to mi mah doeh pakoeh o ai.
8 “Báwo ni èmi ó ṣe fi ọ́ sílẹ̀, Efraimu? Báwo ni èmi ó ṣe yọ̀ǹda rẹ̀, Israẹli? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Adma? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Seboimu? Ọkàn mi yípadà nínú mi àánú mi sì ru sókè.
Ephraim, kawbang maw nang hae kang pahnawt sut thai tih? Israel, kawbang maw nang hae kang prawt sut thai tih? Admah vangpui nuiah ka sak ih hmuen baktiah kawbang maw nang hae ka sah han? Nang hae kawbang maw Zeboiim baktiah kang suem thai tih? Ka poekhaih palung amkhraih moe, pop parai tahmenhaih to ka tawnh boeh.
9 Èmi kò ni mú ìbínú gbígbóná mi ṣẹ, tàbí kí èmi wá sọ Efraimu di ahoro. Nítorí pé èmi ni Ọlọ́run, àní, èmi kì í ṣe ènìyàn. Ẹni mímọ́ láàrín yín, Èmi kò ní í wá nínú ìbínú.
Kanung parai palung ka phuihaih hoiah hmuen to ka sah mak ai, Ephraim to kam rosak mak ai: kai loe kami na ai, Sithaw ni; nangcae salakah kaom Ciimcai Sithaw ah ka oh; to pongah vangpui amrosak hanah kang zo mak ai.
10 Wọn yóò máa tẹ̀lé Olúwa; òun yóò bú ramúramù bí i kìnnìún. Nígbà tó bá bú, àwọn ọmọ rẹ yóò wá ní ìwárìrì láti ìwọ̀-oòrùn.
Nihcae mah Angraeng to patom o tih: Anih loe kaipui baktiah hang tih: Anih hangh naah, a caanawk tasoeh o ueloe, niduem bang hoiah angzo o tih.
11 Wọn ó wá pẹ̀lú ẹ̀rù bí i ẹyẹ láti Ejibiti, bí i àdàbà láti Asiria, Èmi ó mú wọn padà sí ilé wọn,” ni Olúwa wí.
Nihcae loe Izip prae ih tavaanawk baktih, Assyria prae ih pahuu baktiah, tasoehhaih hoiah angzo o tih: to naah nihcae to angmacae im ah ka ohsak han, tiah Angraeng mah thuih.
12 Efraimu tí fi irọ́ yí mi ká ilé Israẹli pẹ̀lú ẹ̀tàn. Ṣùgbọ́n Juda sì dúró ṣinṣin pẹ̀lú Ọlọ́run. Ó sì ṣe olóòtítọ́ sí Ẹni mímọ́ Israẹli.
Lok amlaihaih hoiah Ephraim mah kai ang takui, Israel imthung takoh mah alinghaih hoiah kai ang takui: toe Judah loe oep kaom Ciimcai Sithaw, Sithaw khae hoiah loklam amkhraeng ving boeh.