< Hebrews 9 >
1 Bẹ́ẹ̀ ni májẹ̀mú àkọ́kọ́ ní ìlànà fún ìsìn àti ibi mímọ́ ti ayé yìí.
ས པྲཐམོ ནིཡམ ཨཱརཱདྷནཱཡཱ ཝིཝིདྷརཱིཏིབྷིརཻཧིཀཔཝིཏྲསྠཱནེན ཙ ཝིཤིཥྚ ཨཱསཱིཏ྄།
2 A gbé àgọ́ kan dìde. Nínú yàrá rẹ̀ àkọ́kọ́ ni a ti rí ọ̀pá fìtílà, tábìlì, àti àkàrà ìfihàn. Èyí tí a ń pè ní ibi mímọ́.
ཡཏོ དཱུཥྱམེཀཾ ནིརམཱིཡཏ ཏསྱ པྲཐམཀོཥྛསྱ ནཱམ པཝིཏྲསྠཱནམིཏྱཱསཱིཏ྄ ཏཏྲ དཱིཔཝྲྀཀྵོ བྷོཛནཱསནཾ དརྴནཱིཡཔཱུཔཱནཱཾ ཤྲེཎཱི ཙཱསཱིཏ྄།
3 Àti lẹ́yìn aṣọ ìkélé kejì, òun ni àgọ́ tí à ń pè ní Ibi Mímọ́ Jùlọ;
ཏཏྤཤྩཱད྄ དྭིཏཱིཡཱཡཱསྟིརཥྐརིཎྱཱ ཨབྷྱནྟརེ ྅ཏིཔཝིཏྲསྠཱནམིཏིནཱམཀཾ ཀོཥྛམཱསཱིཏ྄,
4 tí ó ní àwo tùràrí wúrà, àti àpótí ẹ̀rí tí a fi wúrà bò yíká, nínú èyí tí ìkòkò wúrà tí ó ní manna gbé wà, àti ọ̀pá Aaroni tí o rúdí, àti àwọn wàláà májẹ̀mú;
ཏཏྲ ཙ སུཝརྞམཡོ དྷཱུཔཱདྷཱརཿ པརིཏཿ སུཝརྞམཎྜིཏཱ ནིཡམམཉྫཱུཥཱ ཙཱསཱིཏ྄ ཏནྨདྷྱེ མཱནྣཱཡཱཿ སུཝརྞགྷཊོ ཧཱརོཎསྱ མཉྫརིཏདཎྜསྟཀྵིཏཽ ནིཡམཔྲསྟརཽ,
5 àti lórí àpótí ni àwọn kérúbù ògo ti i síji bo ìtẹ́ àánú; èyí tí a kò lè sọ̀rọ̀ rẹ̀ nísinsin yìí lọ́kọ̀ọ̀kan.
ཏདུཔརི ཙ ཀརུཎཱསནེ ཚཱཡཱཀཱརིཎཽ ཏེཛོམཡཽ ཀིརཱུབཱཝཱསྟཱམ྄, ཨེཏེཥཱཾ ཝིཤེཥཝྲྀཏྟཱནྟཀཐནཱཡ ནཱཡཾ སམཡཿ།
6 Ǹjẹ́ nígbà tí a ti ṣe ètò nǹkan wọ̀nyí báyìí, àwọn àlùfáà a máa lọ nígbàkígbà sínú àgọ́ èkínní, wọn a máa ṣe iṣẹ́ ìsìn.
ཨེཏེཥྭཱིདྲྀཀ྄ ནིརྨྨིཏེཥུ ཡཱཛཀཱ ཨཱིཤྭརསེཝཱམ྄ ཨནུཏིཥྛནཏོ དཱུཥྱསྱ པྲཐམཀོཥྛཾ ནིཏྱཾ པྲཝིཤནྟི།
7 Ṣùgbọ́n sínú èkejì ni olórí àlùfáà nìkan máa ń lọ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo lọ́dún, fún ara rẹ̀, àti fún ìṣìnà àwọn ènìyàn.
ཀིནྟུ དྭིཏཱིཡཾ ཀོཥྛཾ པྲཏིཝརྵམ྄ ཨེཀཀྲྀཏྭ ཨེཀཱཀིནཱ མཧཱཡཱཛཀེན པྲཝིཤྱཏེ ཀིནྟྭཱཏྨནིམིཏྟཾ ལོཀཱནཱམ྄ ཨཛྙཱནཀྲྀཏཔཱཔཱནཱཉྩ ནིམིཏྟམ྄ ཨུཏྶརྫྫནཱིཡཾ རུདྷིརམ྄ ཨནཱདཱཡ ཏེན ན པྲཝིཤྱཏེ།
8 Ẹ̀mí Mímọ́ ń tọ́ka èyí pé a kò ì tí ì ṣí ọ̀nà Ibi Mímọ́ Jùlọ sílẹ̀ níwọ̀n ìgbà tí àgọ́ èkínní bá sì dúró,
ཨིཏྱནེན པཝིཏྲ ཨཱཏྨཱ ཡཏ྄ ཛྙཱཔཡཏི ཏདིདཾ ཏཏ྄ པྲཐམཾ དཱུཥྱཾ ཡཱཝཏ྄ ཏིཥྛཏི ཏཱཝཏ྄ མཧཱཔཝིཏྲསྠཱནགཱམཱི པནྠཱ ཨཔྲཀཱཤིཏསྟིཥྛཏི།
9 èyí tí i ṣe àpẹẹrẹ fún ìgbà ìsinsin yìí. Gẹ́gẹ́ bí ètò yìí, a ń mú ẹ̀bùn àti ẹbọ wá, tí kò lè mú ẹ̀rí ọkàn olùsìn di pípé.
ཏཙྩ དཱུཥྱཾ ཝརྟྟམཱནསམཡསྱ དྲྀཥྚཱནྟཿ, ཡཏོ ཧེཏོཿ སཱམྤྲཏཾ སཾཤོདྷནཀཱལཾ ཡཱཝད྄ ཡནྣིརཱུཔིཏཾ ཏདནུསཱརཱཏ྄ སེཝཱཀཱརིཎོ མཱནསིཀསིདྡྷིཀརཎེ྅སམརྠཱབྷིཿ
10 Èyí sì wà nínú ohun jíjẹ àti ohun mímu àti onírúurú ìwẹ̀, tí í ṣe ìlànà ti ara nìkan tí a fi lélẹ̀ títí fi di ìgbà àtúnṣe.
ཀེཝལཾ ཁཱདྱཔེཡེཥུ ཝིཝིདྷམཛྫནེཥུ ཙ ཤཱརཱིརིཀརཱིཏིབྷི ཪྻུཀྟཱནི ནཻཝེདྱཱནི བལིདཱནཱནི ཙ བྷཝནྟི།
11 Ṣùgbọ́n nígbà tí Kristi dé bí olórí àlùfáà àwọn ohun rere tí ń bọ̀, nípasẹ̀ àgọ́ tí o tóbi ti ó sì pé ju ti ìṣáájú, èyí tí a kò fi ọwọ́ dá, èyí yìí ni, tí kì í ṣe ti ẹ̀dá yìí.
ཨཔརཾ བྷཱཝིམངྒལཱནཱཾ མཧཱཡཱཛཀཿ ཁྲཱིཥྚ ཨུཔསྠཱཡཱཧསྟནིརྨྨིཏེནཱརྠཏ ཨེཏཏྶྲྀཥྚེ རྦཧིརྦྷཱུཏེན ཤྲེཥྛེན སིདྡྷེན ཙ དཱུཥྱེཎ གཏྭཱ
12 Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe nípasẹ̀ ẹ̀jẹ̀ ewúrẹ́ àti ọmọ màlúù, ṣùgbọ́n nípa ẹ̀jẹ̀ òun tìkára rẹ̀, o wọ Ibi Mímọ́ Jùlọ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, lẹ́yìn tí ó ti rí ìdáǹdè àìnípẹ̀kun gbà fún wa. (aiōnios )
ཚཱགཱནཱཾ གོཝཏྶཱནཱཾ ཝཱ རུདྷིརམ྄ ཨནཱདཱཡ སྭཱིཡརུདྷིརམ྄ ཨཱདཱཡཻཀཀྲྀཏྭ ཨེཝ མཧཱཔཝིཏྲསྠཱནཾ པྲཝིཤྱཱནནྟཀཱལིཀཱཾ མུཀྟིཾ པྲཱཔྟཝཱན྄། (aiōnios )
13 Nítorí bí ẹ̀jẹ̀ ewúrẹ́ àti ti akọ màlúù àti eérú ẹgbọrọ abo màlúù tí a fi wọ́n àwọn tí a ti sọ di aláìmọ́ ba ń sọ ni di mímọ́ fún ìwẹ̀nùmọ́ ara:
ཝྲྀཥཚཱགཱནཱཾ རུདྷིརེཎ གཝཱིབྷསྨནཿ པྲཀྵེཔེཎ ཙ ཡདྱཤུཙིལོཀཱཿ ཤཱརཱིརིཤུཙིཏྭཱཡ པཱུཡནྟེ,
14 mélòó mélòó ni ẹ̀jẹ̀ Kristi, ẹni, nípa Ẹ̀mí ayérayé, tí ó fi ara rẹ̀ rú ẹbọ sí Ọlọ́run láìní àbàwọ́n, yóò wẹ èérí ọkàn yín nù kúrò nínú òkú iṣẹ́ láti sin Ọlọ́run alààyè? (aiōnios )
ཏརྷི ཀིཾ མནྱདྷྭེ ཡཿ སདཱཏནེནཱཏྨནཱ ནིཥྐལངྐབལིམིཝ སྭམེཝེཤྭརཱཡ དཏྟཝཱན྄, ཏསྱ ཁྲཱིཥྚསྱ རུདྷིརེཎ ཡུཥྨཱཀཾ མནཱཾསྱམརེཤྭརསྱ སེཝཱཡཻ ཀིཾ མྲྀཏྱུཛནཀེབྷྱཿ ཀརྨྨབྷྱོ ན པཝིཏྲཱིཀཱརིཥྱནྟེ? (aiōnios )
15 Àti nítorí èyí ni ó ṣe jẹ́ alárinà májẹ̀mú tuntun pé bí ikú ti ń bẹ fún ìdáǹdè àwọn ìrékọjá ti o tí wà lábẹ́ májẹ̀mú ìṣáájú, kí àwọn tí a ti pè lè rí ìlérí ogún àìnípẹ̀kun gbà. (aiōnios )
ས ནཱུཏནནིཡམསྱ མདྷྱསྠོ྅བྷཝཏ྄ ཏསྱཱབྷིཔྲཱཡོ྅ཡཾ ཡཏ྄ པྲཐམནིཡམལངྒྷནརཱུཔཔཱཔེབྷྱོ མྲྀཏྱུནཱ མུཀྟཽ ཛཱཏཱཡཱམ྄ ཨཱཧཱུཏལོཀཱ ཨནནྟཀཱལཱིཡསམྤདཿ པྲཏིཛྙཱཕལཾ ལབྷེརན྄། (aiōnios )
16 Nítorí níbi tí ìwé ogún bá gbé wà, ikú ẹni tí o ṣe é kò lè ṣe àìsí pẹ̀lú;
ཡཏྲ ནིཡམོ བྷཝཏི ཏཏྲ ནིཡམསཱདྷཀསྱ བལེ རྨྲྀཏྱུནཱ བྷཝིཏཝྱཾ།
17 nítorí ìwé ogún ní agbára lẹ́yìn ìgbà tí ènìyàn bá kú, nítorí kò ní agbára rárá nígbà tí ẹni tí o ṣè e bá ń bẹ láààyè.
ཡཏོ ཧཏེན བལིནཱ ནིཡམཿ སྠིརཱིབྷཝཏི ཀིནྟུ ནིཡམསཱདྷཀོ བལི ཪྻཱཝཏ྄ ཛཱིཝཏི ཏཱཝཏ྄ ནིཡམོ ནིརརྠཀསྟིཥྛཏི།
18 Nítorí náà ni a kò ṣe ya májẹ̀mú ìṣáájú pàápàá sí mímọ́ láìsí ẹ̀jẹ̀.
ཏསྨཱཏ྄ ས པཱུཪྻྭནིཡམོ྅པི རུདྷིརཔཱཏཾ ཝིནཱ ན སཱདྷིཏཿ།
19 Nítorí nígbà tí Mose ti sọ gbogbo àṣẹ nípa ti òfin fún gbogbo àwọn ènìyàn, ó mú ẹ̀jẹ̀ ọmọ màlúù àti ti ewúrẹ́, pẹ̀lú omi, àti òwú òdòdó, àti ewé hísópù ó sì fi wọ́n àti ìwé pàápàá àti gbogbo ènìyàn.
ཕལཏཿ སཪྻྭལོཀཱན྄ པྲཏི ཝྱཝསྠཱནུསཱརེཎ སཪྻྭཱ ཨཱཛྙཱཿ ཀཐཡིཏྭཱ མཱུསཱ ཛལེན སིནྡཱུརཝརྞལོམྣཱ ཨེཥོཝཏྲྀཎེན ཙ སཱརྡྡྷཾ གོཝཏྶཱནཱཾ ཚཱགཱནཱཉྩ རུདྷིརཾ གྲྀཧཱིཏྭཱ གྲནྠེ སཪྻྭལོཀེཥུ ཙ པྲཀྵིཔྱ བབྷཱཥེ,
20 Wí pé, “Èyí ní ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú tí Ọlọ́run pàṣẹ fún yín.”
ཡུཥྨཱན྄ ཨདྷཱིཤྭརོ ཡཾ ནིཡམཾ ནིརཱུཔིཏཝཱན྄ ཏསྱ རུདྷིརམེཏཏ྄།
21 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ó sì fi ẹ̀jẹ̀ wọ́n àgọ́, àti gbogbo ohun èlò ìsìn.
ཏདྭཏ྄ ས དཱུཥྱེ྅པི སེཝཱརྠཀེཥུ སཪྻྭཔཱཏྲེཥུ ཙ རུདྷིརཾ པྲཀྵིཔྟཝཱན྄།
22 Ó sì fẹ́rẹ̀ jẹ́ ohun gbogbo ni a fi ẹ̀jẹ̀ wẹ̀nù gẹ́gẹ́ bí òfin; àti pé láìsí ìtàjẹ̀ sílẹ̀ kò sí ìdáríjì.
ཨཔརཾ ཝྱཝསྠཱནུསཱརེཎ པྲཱཡཤཿ སཪྻྭཱཎི རུདྷིརེཎ པརིཥྐྲིཡནྟེ རུདྷིརཔཱཏཾ ཝིནཱ པཱཔམོཙནཾ ན བྷཝཏི ཙ།
23 Nítorí náà a kò lè ṣàì fi ìwọ̀nyí wé àwọn àpẹẹrẹ ohun tí ń bẹ lọ́run mọ́; ṣùgbọ́n ó yẹ kí a fi ẹbọ tí ó sàn ju ìwọ̀nyí lọ wẹ àwọn ohun ọ̀run pàápàá mọ́; ṣùgbọ́n ó yẹ kí a fi ẹbọ tí ó sàn ju ìwọ̀nyí lọ wẹ àwọn ohun ọ̀run pàápàá mọ́.
ཨཔརཾ ཡཱནི སྭརྒཱིཡཝསྟཱུནཱཾ དྲྀཥྚཱནྟཱསྟེཥཱམ྄ ཨེཏཻཿ པཱཝནམ྄ ཨཱཝཤྱཀམ྄ ཨཱསཱིཏ྄ ཀིནྟུ སཱཀྵཱཏ྄ སྭརྒཱིཡཝསྟཱུནཱམ྄ ཨེཏེབྷྱཿ ཤྲེཥྛེ རྦལིདཱནཻཿ པཱཝནམཱཝཤྱཀཾ།
24 Nítorí Kristi kò wọ ibi mímọ́ tí a fi ọwọ́ ṣe lọ tí i ṣe àpẹẹrẹ ti òtítọ́; ṣùgbọ́n ó lọ sí ọ̀run pàápàá, nísinsin yìí láti farahàn ní iwájú Ọlọ́run fún wa.
ཡཏཿ ཁྲཱིཥྚཿ སཏྱཔཝིཏྲསྠཱནསྱ དྲྀཥྚཱནྟརཱུཔཾ ཧསྟཀྲྀཏཾ པཝིཏྲསྠཱནཾ ན པྲཝིཥྚཝཱན྄ ཀིནྟྭསྨནྣིམིཏྟམ྄ ཨིདཱནཱིམ྄ ཨཱིཤྭརསྱ སཱཀྵཱད྄ ཨུཔསྠཱཏུཾ སྭརྒམེཝ པྲཝིཥྚཿ།
25 Kì í sí i ṣe pé kí ó lè máa fi ara rẹ̀ rú ẹbọ nígbàkígbà, bí olórí àlùfáà tí máa ń wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ lọ lọ́dọọdún ti òun pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ti kì í ṣe tirẹ̀,
ཡཐཱ ཙ མཧཱཡཱཛཀཿ པྲཏིཝརྵཾ པརཤོཎིཏམཱདཱཡ མཧཱཔཝིཏྲསྠཱནཾ པྲཝིཤཏི ཏཐཱ ཁྲཱིཥྚེན པུནཿ པུནརཱཏྨོཏྶརྒོ ན ཀརྟྟཝྱཿ,
26 bí bẹ́ẹ̀ bá ni, òun ìbá tí máa jìyà nígbàkígbà láti ìpìlẹ̀ ayé. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ni ó fi ara hàn lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo lópin ayé láti mu ẹ̀ṣẹ̀ kúrò nípa ẹbọ ara rẹ̀. (aiōn )
ཀརྟྟཝྱེ སཏི ཛགཏཿ སྲྀཥྚིཀཱལམཱརབྷྱ བཧུཝཱརཾ ཏསྱ མྲྀཏྱུབྷོག ཨཱཝཤྱཀོ྅བྷཝཏ྄; ཀིནྟྭིདཱནཱིཾ ས ཨཱཏྨོཏྶརྒེཎ པཱཔནཱཤཱརྠམ྄ ཨེཀཀྲྀཏྭོ ཛགཏཿ ཤེཥཀཱལེ པྲཙཀཱཤེ། (aiōn )
27 Níwọ́n bí a sì ti fi lélẹ̀ fún gbogbo ènìyàn láti kú lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí ìdájọ́,
ཨཔརཾ ཡཐཱ མཱནུཥསྱཻཀཀྲྀཏྭོ མརཎཾ ཏཏ྄ པཤྩཱད྄ ཝིཙཱརོ ནིརཱུཔིཏོ྅སྟི,
28 bẹ́ẹ̀ ni Kristi pẹ̀lú lẹ́yìn tí a ti fi rú ẹbọ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo láti ru ẹ̀ṣẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀, yóò farahàn ní ìgbà kejì láìsí ẹ̀ṣẹ̀ fún àwọn tí n wo ọ̀nà rẹ̀ fún ìgbàlà.
ཏདྭཏ྄ ཁྲཱིཥྚོ྅པི བཧཱུནཱཾ པཱཔཝཧནཱརྠཾ བལིརཱུཔེཎཻཀཀྲྀཏྭ ཨུཏྶསྲྀཛེ, ཨཔརཾ དྭིཏཱིཡཝཱརཾ པཱཔཱད྄ བྷིནྣཿ སན྄ ཡེ ཏཾ པྲཏཱིཀྵནྟེ ཏེཥཱཾ པརིཏྲཱཎཱརྠཾ དརྴནཾ དཱསྱཏི།