< Hebrews 8 >
1 Nísinsin yìí, kókó ohun tí à ń sọ nìyí. Àwa ní irú olórí àlùfáà bẹ́ẹ̀, tí ó jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún ìtẹ́ Ọláńlá nínú àwọn ọ̀run,
Eshi nongwa zyatiyanga zya zyezi: tilinawo odimi ogosi yakheyepansi huuchoolelo owa itengo elyeenzi mwanya.
2 Ìránṣẹ́ ibi mímọ́, àti ti àgọ́ tòótọ́, tí Olúwa pa, kì í ṣe ènìyàn.
Emwene dimo wadimiatakatifu, emputilo eyeloli ambaogosi abheshele siumnte wawonti ya mfwa.
3 Nítorí a fi olórí àlùfáà kọ̀ọ̀kan jẹ láti máa mú ẹ̀bùn wá láti máa rú ẹbọ, nítorí náà ó ṣe pàtàkì fún eléyìí náà láti ní nǹkan tí ó máa fi sílẹ̀.
Shila dimi ogosi abhewha afumie ezawadi ne dhabihu; kwa hiyo shinza abhenahantu ahafumie.
4 Tí ó bá jẹ́ pé ó wà ní ayé ni, òun kì bá ti jẹ́ àlùfáà, nítorí pé àwọn ọkùnrin tí ó ń fi ẹ̀bùn sílẹ̀ ti wà bí òfin ṣe là á sílẹ̀.
Eshi nkashele oKristi alipa mwanya pansi amwene nanda sagali dimi lwesho. Afwataneje bhalitayalibhwala fumizye, evipawa alengane nendapizyo.
5 Àwọn ẹni tí ń jọ́sìn nínú pẹpẹ kan tí ó jẹ́ àpẹẹrẹ àti òjìji ohun tí ń bẹ ní ọ̀run. Ìdí abájọ nìyí tí a fi kìlọ̀ fún Mose nígbà tí ó fẹ́ kọ́ àgọ́, nítorí ó wí pé, “Kíyèsí i, kí ìwọ kí ó ṣe wọ́n gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ wọn, ti a fi hàn ọ́ ni orí òkè.”
Bhabhombile ahantu hahalu hasageye vintu evyamwanya swa nashi oMusa nakhajilwaga no Ngolobhe. “Lula,” Ongolobhe ayanjile, “shila hantu alengane neshilenga nyizyo shohalangwile pamwanya pigamba.”
6 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí o ti gba iṣẹ́ ìránṣẹ́ tí ó ni ọlá jù, níwọ̀n bí o ti jẹ pé alárinà májẹ̀mú tí o dára jù ní i ṣe, èyí tí a fi ṣe òfin lórí ìlérí tí o sàn jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Lelo eshi oKristi aposheye embombo enyinza tee afatanaje umwene nantele yalenganya wegano enyiza, lyalilenganyiziwe elenguvu enyinza.
7 Nítorí ìbá ṣe pé májẹ̀mú ìṣáájú nì kò ní àbùkù, ǹjẹ́ a kì bá ti wá ààyè fún èkejì.
Heshi nkashele olagano olwa whande handa selwali namakosa handa setali ne haja ahwanze ilagano elyabhele.
8 Nítorí tí ó rí àbùkù lára wọn, ó wí pé, “Ìgbà kan ń bọ̀, ni Olúwa wí, tí Èmi yóò bá ilé Israẹli àti ilé Juda dá májẹ̀mú tuntun.
Afwatanaje Ongolobhe nagahama manya amakosa agabhantu ayanjile, “Enya, ensiku zihwenza ayanga oGosi, 'owakati embalenganye ilagano ipya pandwemo ne nyumba ya Israeli, ne nyumba iya Yuda.
9 Kì í ṣe gẹ́gẹ́ bí májẹ̀mú tí mo ti bá àwọn baba baba wọn dá, nígbà tí mo fà wọ́n lọ́wọ́ láti mú wọn jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti, nítorí wọn kò jẹ́ olóòtítọ́ sí májẹ̀mú mi èmi kò sì ta wọ́n nu, ni Olúwa wí.
Sagalibhabhe nashi ilagano lyalyabhombeshe pandemo na bababhabho isikunehabhejile humakhono abhalongozye afume hunsi ya Misri. Afataneje sebhahendeleye hwilagano lyane, nanesenabhasajile nantele ayanga oGosi.
10 Nítorí èyí ni májẹ̀mú tí èmi yóò bá ilé Israẹli dá lẹ́yìn àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ni Olúwa wí. Èmi ó fi òfin mi sí inú wọn, èmi ó sì kọ wọ́n sí ọkàn wọn, èmi ó sì máa jẹ́ Ọlọ́run fún wọn, wọn ó sì máa jẹ́ ènìyàn fún mi.
Afwateje eli lilagano embalibhombe hunyumba eya Israeli hunsiku ezi,' ayanga Ogosi. 'emabheshe endajizyo zyane hunsebho zyabho, embasimbe humo yogabho embabhe Ngolobhe wao, bhape bhabhe bhantu bhane.
11 Olúkúlùkù kò ní tún máa kọ́ ara ìlú rẹ̀, tàbí olúkúlùkù arákùnrin rẹ̀, pé, ‘Mọ Olúwa,’ nítorí pé gbogbo wọn ni yóò mọ̀ mí, láti kékeré dé àgbà.
Sebhabhamanyizanye kila mntu no jilani wakwe, na kila mntu noholo wakwe, nkayanjile, “Mmanyaje aje yo Gosi, “bhonti bhabhamanyeane ahwande umwana hadi ogasiwao.
12 Nítorí pé èmi ó ṣàánú fún àìṣòdodo wọn, àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn àti àìṣedéédéé wọn lèmi ki yóò sì rántí mọ́.”
Embalanje ulusajilo humbombo zyabho zyashelesezyi haki, nasembazizushe embibhi zyabho nantele.”
13 Ní èyí tí ó wí pé, májẹ̀mú títún ó ti sọ ti ìṣáájú di ti láéláé. Ṣùgbọ́n èyí tí ó ń di i ti láéláé tí ó sì ń gbó, o múra àti di asán.
Senayanga “Mpya,” abhombile ilagano elyahwande abhe ligosi ligosi. Na elyo lyalitangazizye abheligosi ligosi lisageye hashe asogole.