< Hebrews 4 >

1 Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run ti ṣe ìlérí àtiwọ inú ìsinmi rẹ̀ fún wa, ẹ jẹ́ kí á bẹ̀rù, kí ẹnikẹ́ni nínú yín má ba à dàbí ẹni pé ó tí kùnà rẹ̀.
tano nyori, bi ma yora kati yilo kange nii fiyabo doka fiye fubkaka wo kwama ma bineneu.
2 Nítorí tí àwa gbọ́ ìwàásù ìyìnrere, gẹ́gẹ́ bí a ti wàásù rẹ̀ fún àwọn náà pẹ̀lú, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ tí wọ́n gbọ́ kò ṣe wọ́n ní àǹfààní, nítorí tí kò dàpọ̀ mọ́ ìgbàgbọ́ nínú àwọn tí ó gbọ́ ọ.
na bi nuwa ker limero fobka nyo ki den kwama na wuro kambo ci yibeu. dila tomange churo chorbo buni ki nubo buro nuwari la chi nebo bilengke ki tomangeu chi nuwau.
3 Nítorí pé àwa tí ó ti gbàgbọ́ wọ inú ìsinmi gẹ́gẹ́ bí ó tí wí, “Bí mo tí búra nínú ìbínú mi, ‘Wọn kì yóò wọ inú ìsinmi mi.’” Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a tí parí iṣẹ́ wọ̀nyí láti ìpìlẹ̀ ayé.
ka nyo, nubo buro nyo ne bilengke nya do fobkaka wuro tiye na wuro ci tike, kambo mi weri mwor funermire, mani ciya do fobka mi koti ci tok nyo, kamob cho dim fwelka diger chere fe-fo ki terka kale.
4 Nítorí ó ti sọ níbìkan ní ti ọjọ́ keje báyìí pé, “Ọlọ́run sì sinmi ní ọjọ́ keje kúrò nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo.”
dige bwiyeu chon tokum fiye kange ki den kume ni bere, kwama fubom ki diye nibere gwam ki nangen chero cho manange.”
5 Àti níhìn-ín yìí pẹ̀lú ó wí pé, “Wọn kì yóò wọ inú ìsinmi mi.”
yila chon tokten, mani chiya fiya doka fobka miti.”
6 Nítorí náà bí ó tí jẹ́ pé, ó ku kí àwọn kan wọ inú rẹ̀, àti àwọn tí a ti wàásù ìyìnrere náà fún ní ìṣáájú kò wọ inú rẹ̀ nítorí àìgbọ́ràn.
tano nyo kambo fobka kwama ma chokum ki chi na chi do'o nyo kambo chi Isralawa ducce nubo buro nuwa tomange wo yori nyoweu, ki den fobka chekeu chi nobe dige bwiyeu cho bongtu chi yeu,
7 Àti pé, ó yan ọjọ́ kan, ó wí nínú ìwé Dafidi pé, “Lónìí,” lẹ́yìn ìgbà pípẹ́ bẹ́ẹ̀; bí a tí wí níṣàájú, “Lónìí bí ẹ̀yin bá gbọ́ ohùn rẹ̀, ẹ má ṣe sé ọkàn yín le.”
kwama nyila nyo dige kange wo chi chuwo tiki “duwen.”cho dok diye wuro ki kwama cho tokker kange Dauda wuro cho tokki fe-fo kutange chi ter tok kakke duwen no kom nuwa dir cherdi kom mare nerkumero nin bongtu.”
8 Nítorí, ìbá ṣe pé Joṣua tí fún wọn ní ìsinmi, òun kì bá tí sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìsinmi mìíràn lẹ́yìn náà,
no tano Joshua ne kom fobkari, kwama no ti fweibo nyoka kange kumetak.
9 nítorí náà ìsinmi kan kù fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run.
tano nyo kume wi, ki kume nukkune wo yom -yowe na fobka che ki nob kwama.
10 Nítorí pé ẹni tí ó ba bọ́ sínú ìsinmi rẹ̀, òun pẹ̀lú sinmi kúrò nínú iṣẹ́ tirẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run ti sinmi kúrò nínú iṣẹ́ tirẹ̀.
di nii wo do-o fobka kwama cho ki bwichi chin nyimom chin fiya fobka nangen chero nin, na wuro kwama ma ki wo ceu.
11 Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á múra gírí láti wọ inú ìsinmi náà, kí ẹnikẹ́ni má ba à ṣubú nípa irú àìgbàgbọ́ kan náà.
tano nyori bima chwika lo fobkakko wureno. kati yilo kangem bo yari ki den bwirangkero chi maneu.
12 Nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run yè, ó sì ní agbára, ó sì mu ju idàkídà olójú méjì lọ, ó sì ń gún ni, àní títí dé pínpín ọkàn àti ẹ̀mí ní yà, àti ní oríkèé àti ọ̀rá inú egungun, òun sì ni olùmọ̀ èrò inú àti ète ọkàn.
ker kwamaro wi ki dume yilo ti chri, chum bitwiye nyiyo cha ti kakko yobeu. mari rerken tiber dume kange yuwa, yilo ko lam nyo bwigkwi. cha ki fuwam mwor nere nyo kange nero chwitiyeu.
13 Kò sí ẹ̀dá kan tí kò farahàn níwájú rẹ̀, ṣùgbọ́n ohun gbogbo ni ó wà níhòhò tí a sì ṣípáyà fún ojú rẹ̀, níwájú ẹni tí àwa yóò jíyìn.
dige kange mani nawo fwelfwele nuwe kwama, dii laka, dige buro ki filange, yilo nyimom nyime fo nuwe che wuro tam kange nure mani ban ne dige dorbere fiye chi wiye.
14 Ǹjẹ́ bí a ti ní olórí àlùfáà ńlá kan, tí ó ti la àwọn ọ̀run kọjá lọ, Jesu Ọmọ Ọlọ́run, ẹ jẹ́ kí a di ìjẹ́wọ́ wa mú ṣinṣin.
kambo binwi nii wabkako dur wurodo tiber dikwama, kiritti bi bwe kwama, dila bi tam bilengkebeu ki bi kwan
15 Nítorí a kò ní olórí àlùfáà tí kò lè ṣàì ba ni kẹ́dùn nínú àìlera wa, ẹni tí a ti dánwò lọ́nà gbogbo gẹ́gẹ́ bí àwa, ṣùgbọ́n òun kò dẹ́ṣẹ̀.
dige bwiyeu nii dur waberbero kebo nii koka chika yarka beko. dige bwiyeu nwuro chi chuwa cho ki nure kalerangi nyowe na wuro chi ma binene, dila chi fiya cho bo ki bwirangke
16 Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí a wá si ibi ìtẹ́ oore-ọ̀fẹ́ pẹ̀lú ìgboyà, kí a lè rí àánú gbà, kí a sì rí oore-ọ̀fẹ́ láti máa ran ni lọ́wọ́ ní àkókò tí ó wọ̀.
di bi bofiye liyar filange twai mani, dige bwiyeu na ma binen taikali na bifiya filangko na wuro ati kang boti ki kwama chwi kake.

< Hebrews 4 >