< Hebrews 2 >
1 Nítorí náà, ó yẹ kí àwa máa fi iyè sí àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì gidigidi tí àwa ti gbọ́, kí a má ba à gbá wa lọ kúrò nínú wọn nígbà kan.
Amaiba: le, ninia mae muguluma: ne, ninia da dafawane sia: amo ninia nabi, amo baligiliwane lalegagumu da defea.
2 Nítorí bí ọ̀rọ̀ tí a tí ẹnu àwọn angẹli sọ bá sì dúró ṣinṣin, àti tí olúkúlùkù ẹ̀ṣẹ̀ sí òfin àti àìgbọ́ràn gba ìjìyà tí ó tọ́ sí i,
Gode da ninia aowalali dunuma olelemusa: a:igele dunu asunasi. Ilia da amo sia: da dafawane ba: i. Nowa dunu da amo sia: nabawane hame hamonoba, e da ea hawa: hamoi amo defele se dabe iasu ba: i.
3 kín ni ohun náà tí ó mú wa lérò pé a lè bọ́ kúrò nínú ìjìyà bí a kò bá náání ìgbàlà ńlá yìí? Ìgbàlà tí Olúwa fúnra rẹ̀ kọ́kọ́ kéde, èyí tí a sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún wa láti ọwọ́ àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà lẹ́nu rẹ̀.
Amaiba: le, ninia da amo gaga: su bagadedafa da hamedeiwane liligi dawa: sea, ninia hobeale masunu logo hamedafa ba: mu. Hina Gode Hisu da hidadea amo gaga: su sia: olelei. Ema ba: su dunu da lalegaguiba: le, amo sia: da dafawane, ninia ba: sa.
4 Ọlọ́run jẹ́rìí sí i nípa àwọn iṣẹ́ àmì àti ìyanu àti oríṣìíríṣìí iṣẹ́ agbára àti nípa ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ tí a pín gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀.
Gode da amo ba: su dunu ilia olelei da dafawane olelemusa: , E da musa: hame ba: i gasa bagade hou bagohame hamosu. E da Ea hanai defele, Ea A: silibu Hadigidafa Gala hahawane fidisu iasu liligi osobo bagade dunu ilima i.
5 Nítorí pé, kì í ṣe abẹ́ ìṣàkóso àwọn angẹli ni ó fi ayé tí ń bọ̀, tí àwa ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ sí.
Gode da hobea misunu gaheabolo osobo bagade (amo ninia da olelesa), amo ouligima: ne a: igele dunu hame ilegei.
6 Ṣùgbọ́n ibìkan wà tí ẹnìkan tí jẹ́rìí pé “Kí ni ènìyàn tí ìwọ fi ń ṣe ìrántí rẹ̀, tàbí ọmọ ènìyàn, tí ìwọ fi ń bẹ̀ ẹ́ wò?
Be Gode Sia: da agoane dedei diala, “Gode! Osobo bagade dunu ilia da hamedei liligi fawane. Amaiba: le, Di da abuliba: le ilima asigiliwane dadawa: sala?
7 Ìwọ dá a ní onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ; ìwọ fi ògo àti ọlá de e ni adé, ìwọ sì fi í jẹ olórí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,
Di da osobo bagade dunu ili fonobahadi ouesaloma: ne, a:igele dunu ilima haguduga ligisi. Be osobo bagade dunu ilima hadigi amola mimogo hou habuga agoane ilima figisi, amola ili liligi huluane ouligima: ne ilegei.”
8 Ìwọ fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.” Ní ti fífi ohun gbogbo sábẹ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n àwa kò ì tí ì rí ohun kan tí ó kù tí kò sí ní abẹ́ àkóso rẹ̀. Síbẹ̀ nísinsin yìí àwa kò ì tí ì rí pé ó fi ohun gbogbo sábẹ́ ìṣàkóso rẹ̀.
Gode Sia: da agoane dedei, “Gode da osobo bagade dunu ilia liligi huluane amoma ouligima: ne ouligisu hamoi.” Amo da “liligi huluane” sia: sa. Be wali, osobo bagade dunu ilia liligi huluanema ouligisu hame esala, amo ninia ba: sa.
9 Ṣùgbọ́n àwa rí Jesu ẹni tí a rẹ̀ sílẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ fún àkókò díẹ̀, àní Jesu, ẹni tí a fi ògo àti ọlá dé ní adé nítorí ìjìyà wa; kí ó lè tọ́ ikú wò fún olúkúlùkù ènìyàn nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.
Be Yesu, E da fonobahadi ouesaloma: ne, a:igele dunu ilima hagudu ligisi, ninia da ba: sa. E da Gode Ea hahawane dogolegele iasu dawa: beba: le, dunu huluane ilia bogosu E da lai dagoi. E da se nabawane bogobeba: le, Gode da Ema hadigi gasa bagade Hina hou i dagoi.
10 Nítorí pé ó yẹ fún Ọlọ́run, nítorí nípasẹ̀ ẹni tí ohun gbogbo ṣẹ̀ wà, láti mú àwọn ọmọ púpọ̀ wá sínú ògo, láti ṣe balógun ìgbàlà wọn ni àṣepé nípa ìjìyà.
Gode da liligi huluane hahamosa amola liligi huluane mae muguluma: ne gagusa. E da Ea mano bagohame Yesu Ea hadigi gilisili lama: ne hamomusa: , Yesu Gelesuma se bagade iasu. Yesu da Ea lalegagui fi dunu gaga: sudafa amoga oule masa: ne, E da amo hou hamoi amola amo hou ninia defeawane ba: sa.
11 Nítorí àti ẹni tí ń sọ ni di mímọ́ àti àwọn tí a ń sọ di mímọ́, láti ọ̀dọ̀ ẹnìkan ṣoṣo ni gbogbo wọn ti wá, nítorí èyí ni kò ṣe tijú láti pè wọ́n ni arákùnrin.
E da dunu ilia wadela: i hou dodofemusa: dawa: E amola Ea fofoloi hamoi dunu, da Ada afadafa esala. Amaiba: le, Yesu da ilima “eya” dio mae gogosiane asula.
12 Àti wí pé, “Èmi ó sọ̀rọ̀ orúkọ rẹ̀ fún àwọn ará mi, ni àárín ìjọ ni èmi yóò kọrin ìyìn rẹ̀.”
E da Godema amane sia: sa, “Na da Naeya ilima Dia hawa: hamoi olelemu. Ilia gilisisu amo ganodini Na da Dima nodomu!”
13 Àti pẹ̀lú, “Èmi yóò gbẹ́kẹ̀ mi lé e.” Àti pẹ̀lú, “Kíyèsi í, èmi rèé, èmi àti àwọn ọmọ tí Ọlọ́run fi fún mi.”
E da Godema eno amane sia: sa, “Gode! Na Dima dafawaneyale dawa: mu.” E eno amane sia: i, “Na amola mano amo Gode da Nama i, da goea.”
14 Ǹjẹ́ ni ìwọ̀n bí àwọn ọmọ tí ṣe alábápín ará àti ẹ̀jẹ̀, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni òun pẹ̀lú sì ṣe alábápín nínú ohun kan náà; kí ó lè ti ipa ikú rẹ̀ pa ẹni tí ó ní agbára ikú run, èyí ni èṣù.
Amo Ea mano (amo dio Yesu da asuli) ilia da hu amola maga: me, amoga hamoiba: le, Yesu da hu amola maga: me lale, Ea osobo bagade mano defele esalusu. Sa: ida: ne da dunu bogoma: ne gasa lai dagoi. Be Yesu da Sa: ida: ne gugunufinisima: ne, bogoi dagoi.
15 Kí o sì lè gba gbogbo àwọn tí ó tìtorí ìbẹ̀rù ikú wà lábẹ́ ìdè lọ́jọ́ ayé wọn gbogbo kúrò lọ́wọ́ ìbẹ̀rù.
E da agoane hamobeba: le, osobo bagade dunu amo da bogomuba: le beda: i, eso huluane se iasu diasuga esalebe dunu agoai ba: su, amo ilia halegale masa: ne, ilia se iasu diasu logo doasi dagoi.
16 Nítorí pé, nítòótọ́, kì í ṣe àwọn angẹli ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún, ṣùgbọ́n àwọn irú-ọmọ Abrahamu ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún.
E da a: igele dunu hame fidisa, amo ninia noga: le ba: sa. Be Gode Sia: da agoane dedei diala, “E da A: ibalaha: me egaga mano fidisa.”
17 Nítorí náà, ó yẹ pé nínú ohun gbogbo kí ó dàbí àwọn ará rẹ̀, kí ó lè jẹ́ aláàánú àti olóòtítọ́ alábojútó Àlùfáà nínú ohun tí i ṣe ti Ọlọ́run, kí o lè ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn.
Bai Yesu da osobo bagade dunu ilia wadela: i hou gogolema: ne olofoi ba: ma: ne, E da ilima mae yolesili, asigiwane Gobele Salasu Ouligisudafa Dunu Godema hawa: hamonana esaloma: ne, E da eya amo defele hu amola maga: me lai dagoi.
18 Nítorí níwọ̀n bí òun tìkára rẹ̀ ti jìyà tí a sì ti dán an wò, òun ní agbára láti ran àwọn tí a ń dánwò lọ́wọ́.
Amola wali E da dunu amo da adoba: su amola se nabasu dawa: , ili fidimusa: dawa: Bai E da ilima doaga: be hou defele, Hisu adoba: su amola se nabasu ba: i dagoi.