< Hebrews 12 >

1 Nítorí náà bí a ti fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ tí o kún fún àwọn ẹlẹ́rìí tó báyìí yí wa ká, ẹ jẹ́ kí a pa ohun ìdíwọ́ gbogbo tì sí apá kan, àti ẹ̀ṣẹ̀ tí o rọrùn láti di mọ́ wa, kí a sì máa fi sùúrù súré ìje tí a gbé ka iwájú wa,
Na, i tenei kapua nui o nga kaiwhakaatu e karapoti nei i a tatou, whakarerea e tatou nga whakataimaha katoa, me te hara whakaeke tata, kia manawanui hoki tatou ki te oma i te omanga e takoto nei i to tatou aroaro;
2 kí a máa wo Jesu Olùpilẹ̀ṣẹ̀ àti aláṣepé ìgbàgbọ́ wa; ẹni nítorí ayọ̀ tí a gbé ka iwájú rẹ, tí o faradà àgbélébùú láìka ìtìjú sí, tí ó sì jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún ìtẹ́ Ọlọ́run.
Me te titiro pu ano ki a Ihu, ki te kaitimata, ki te kaiwhakaoti i te whakapono; i whakaaro hoki ia ki te hari i tona aroaro, a whakamanawanui ana ki te ripeka, whakahawea ana ki te whakama, na kua noho ki matau o te torona o te Atua.
3 Máa ro ti ẹni tí ó faradà irú ìsọ̀rọ̀-òdì yìí láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ si ara rẹ̀, kí ẹ má ba á rẹ̀wẹ̀sì ni ọkàn yín, kí àárẹ̀ si mu yín.
Whakaaroa hoki ia i whakamanawanui nei ki taua totohe nui a te hunga hara ki a ia, kei hoha o koutou ngakau, kei ngakaukore koutou.
4 Ẹ̀yin kò sá à tí ì kọ ojú ìjà si ẹ̀ṣẹ̀ títí dé títa ẹ̀jẹ̀ yín sílẹ̀ nínú ìjàkadì yín.
Ko ta koutou pakanga, kahore ano kia tae noa ki te toto i a koutou e whawhai na ki te hara.
5 Ẹ̀yin sì ti gbàgbé ọ̀rọ̀ ìyànjú tí ó n ba yin sọ̀rọ̀ bí ọmọ pé, “Ọmọ mi, ma ṣe aláìnání ìbáwí Olúwa, kí o má sì ṣe rẹ̀wẹ̀sì nígbà tí a bá ń ti ọwọ́ rẹ̀ ba ọ wí,
A kua wareware koutou ki te kupu whakahau e korero nei ki a koutou, me te mea he tama koutou, E taku tama, kaua e whakahawea ki ta te Ariki papaki; kei ngakaukore hoki ina riria e ia:
6 nítorí pé ẹni ti Olúwa fẹ́, òun ni i bá wí, a sì máa na olúkúlùkù ọmọ tí òun tẹ́wọ́gbà.”
E papaki ana hoki te Ariki ki tana e aroha ai, e whiua ana hoki e ia nga tama katoa e whakatamarikitia ana ki a ia.
7 Ẹ máa ní sùúrù lábẹ́ ìbáwí, Ọlọ́run bá wa lò bí ọmọ ni; nítorí pé ọmọ wo ni ń bẹ ti baba kì í bá wí?
Hei pakinga ta koutou e manawanui ai; e rite ana ta te Atua meatanga ki a koutou ki tana ki nga tama tupu; ko wai hoki te tama e kore e pakia e tona papa?
8 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin ba wà láìsí ìbáwí, nínú èyí tí gbogbo ènìyàn ti jẹ alábápín, ǹjẹ́ ọmọ àlè ni yín, ẹ kì í sì ṣe ọmọ.
Ki te kahore ia o koutou pakinga, te mea e whakawhiwhia ana ki te katoa, he poriro koutou, ehara i te tama.
9 Pẹ̀lúpẹ̀lú àwa ni baba wa nípa ti ara tí o ń tọ́ wa, àwa sì ń bu ọlá fún wọn: kò ha yẹ kí a kúkú tẹríba fún Baba àwọn ẹ̀mí, kí a sì yè?
Tetahi, he matua ano o tatou no te wahi ki te kikokiko, he mea papaki tatou na ratou; i hopohopo ano tatou ki a ratou: kaua ianei e nui noa atu to tatou ngohengohe ki te Matua o nga wairua, kia ora ai?
10 Nítorí wọ́n tọ́ wa fún ọjọ́ díẹ̀ bí o bá ti dára lójú wọn; ṣùgbọ́n Òun tọ́ wa fún èrè wa, kí àwa lè ṣe alábápín ìwà mímọ́ rẹ̀.
Ko ta ratou papaki hoki he torutoru nei nga ra, he mea ano na ta ratou ake i whakaaro ai; ko ta tenei ia hei pai mo tatou, kia whiwhi ai tatou ki tona tapu.
11 Gbogbo ìbáwí kò dàbí ohun ayọ̀ nísinsin yìí bí kò ṣe ìbànújẹ́; ṣùgbọ́n níkẹyìn yóò so èso àlàáfíà fún àwọn tí a tọ́ nípa rẹ̀, àní èso òdodo.
Ko nga pakinga katoa, e kore e kiia inaianei hei whakahari, engari hei whakapouri: muri iho ia ka puta mai te hua rangimarie o te tika, ki te hunga e whakamahia ana ki taua mea.
12 Nítorí náà, ẹ na ọwọ́ tí ó rọ, àti eékún àìlera,
Heoi kia ara nga ringaringa kua tukua iho, me nga turi ngoikore:
13 “Kí ẹ sì ṣe ipa ọ̀nà tí ó tọ́ fún ẹsẹ̀ yin,” kí èyí tí ó rọ má bá a kúrò lórí ike ṣùgbọ́n kí a kúkú wò ó sàn.
Hanga hoki etahi huarahi tika mo o koutou waewae, kei whakapeaua ketia atu te kopa; engari kia ora ake i te mate.
14 Ẹ máa lépa àlàáfíà pẹ̀lú ènìyàn gbogbo, àti ìwà mímọ́, láìsí èyí yìí kò sí ẹni tí yóò rí Olúwa.
Whaia te rongo kia mau ki te katoa, me te tapu hoki, ki te kahore hoki tenei e kore tetahi tangata e kite i te Ariki.
15 Ẹ máa kíyèsára kí ẹnikẹ́ni má ṣe kùnà Oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run; kí gbòǹgbò ìkorò kan máa ba hù sókè kí ó sì yọ yín lẹ́nu, ọ̀pọ̀lọpọ̀ a sì ti ipa rẹ̀ di àìmọ́.
Me te titiro marie kei hapa tetahi i to te Atua aroha noa; kei pihi ake tetahi pakiaka o te kawa hei whakararuraru, e poke ai te tokomaha;
16 Kí o má bá à si àgbèrè kan tàbí aláìwà-bí-Ọlọ́run bi Esau, ẹni tí o tìtorí òkèlè oúnjẹ kan ta ogún ìbí rẹ̀.
Kei moepuku tetahi, kei whakarihariha ranei, kei pera me Ehau: i hokona ra e ia tona matamuatanga ki te kainga kotahi.
17 Nítorí ẹ̀yin mọ pé lẹ́yìn náà, nígbà tí ó fẹ́ láti jogún ìbùkún náà, a kọ̀ ọ́, nítorí kò ri ààyè ìrònúpìwàdà, bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ó fi omijé wa a gidigidi.
E matau ana hoki koutou ki tona hiahia i muri kia riro i a ia te manaaki, a kapea ana ia: kihai hoki i kitea he wahi mo te ripeneta; i rapua marietia ano e ia me te heke ano o nga roimata.
18 Nítorí ẹ̀yin kò wá òkè tí a lè fi ọwọ́ kàn, àti ti iná ti ń jó, àti ti ìṣúdudu àti òkùnkùn, àti ìjì.
Ehara hoki i te mea kua tae koutou ki te maunga e taea te whakapa atu, ki te ahi e ka ana, ki te pango kerekere, ki te pouri, ki te tupuhi,
19 Àti ìró ìpè, àti ohùn ọ̀rọ̀, èyí tí àwọn tí o gbọ́ bẹ̀bẹ̀ pé, kí a má ṣe sọ ọ̀rọ̀ sí i fún wọn mọ́,
Ki te tangi o te tetere, ki te reo e korero ana; i inoi ra te hunga i rangona ai kia kaua he kupu ki a ratou i muri iho:
20 nítorí pé wọn kò lè gba ohun tí ó paláṣẹ, “Bí o tilẹ̀ jẹ ẹranko ni ó fi ara kan òkè náà, a ó sọ ọ́ ni òkúta.”
Kihai hoki ratou i kaha ake ki te mea i whakaritea mai, Na, ahakoa he kararehe e pa atu ki te maunga, me aki ki te kohatu;
21 Ìran náà sì lẹ́rù to bẹ́ẹ̀ tí Mose wí pé, “Ẹ̀rù ba mi gidigidi mo sì wárìrì.”
Koia ano te mataku o te mea i puta mai ra, i mea ai a Mohi, Mataku rawa ahau, wiri rawa:
22 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wá sí òkè Sioni, àti sí ìlú Ọlọ́run alààyè, ti Jerusalẹmu ti ọ̀run, àti si ẹgbẹ́ àwọn angẹli àìníye,
Engari kua tae nei koutou ki Maunga Hiona, ki te pa o te Atua ora, ki Hiruharama i te rangi, ki nga mano tini o nga anahera,
23 si àjọ ńlá tí ìjọ àkọ́bí tí a ti kọ orúkọ wọn ni ọ̀run, àti sọ́dọ̀ Ọlọ́run onídàájọ́ gbogbo ènìyàn, àti sọ́dọ̀ àwọn ẹ̀mí olóòtítọ́ ènìyàn tí a ṣe ni àṣepé,
Ki te huihui nui, ki te hahi o nga matamua, kua oti te tuhituhi ki te rangi, ki te Atua hoki, ki te kaiwhakawa o nga tangata katoa, ki nga wairua ano o te hunga tika kua oti te mea kia tino tika,
24 àti sọ́dọ̀ Jesu alárinà májẹ̀mú tuntun, àti si ibi ẹ̀jẹ̀ ìbùwọ́n ni, ti ń sọ̀rọ̀ ohun tí ó dára ju ti Abeli lọ.
Ki a Ihu ano hoki, ki te takawaenga o te kawenata hou, ki nga toto o te tauhiuhinga, he pai ake nei nga korero i to Apera.
25 Kíyèsi i, kí ẹ má ṣe kọ̀ ẹni tí ń kìlọ̀. Nítorí bí àwọn wọ̀nyí kò bá bọ́ nígbà tí wọn kọ̀ ẹni ti ń kìlọ̀ ni ayé, mélòó mélòó ni àwa kì yóò bọ́, bí àwa ba pẹ̀yìndà sí ẹni tí ń kìlọ̀ láti ọ̀run wá,
Kia mahara kei whakarere koutou i tenei e korero mai nei. Ki te mea hoki kihai i mawhiti te hunga i paopao ki tera i korero ra i runga i te whenua, ina e kore rawa ano tatou, ki te tahuri ke atu i tenei kua korero mai nei i te rangi:
26 ohùn ẹni tí ó mi ayé nígbà náà, ṣùgbọ́n nísinsin yìí o ti ṣe ìlérí, wí pé, “Lẹ́ẹ̀kan sí i èmi ki yóò mi kìkì ayé nìkan, ṣùgbọ́n ọ̀run pẹ̀lú.”
Ngaueue ana te whenua i tona reo i reira: inaianei ia kua puaki tana kupu whakaari, kua mea ia, Kia kotahi ano meatanga, a ehara i te mea ko te whenua anake, ko te rangi ano hoki taku e whakangaueue ai.
27 Àti ọ̀rọ̀ yìí, “Lẹ́ẹ̀kan sí i,” ìtumọ̀ rẹ̀ ni, mímú àwọn ohun wọ̀nyí ti a ń mì kúrò, bí ohun tí a ti dá, kí àwọn ohun tí a kò lè mì lè wà síbẹ̀.
Ko taua kupu nei hoki, Kia kotahi meatanga, hei whakakite i te putanga ketanga o nga mea ka whakangaueuetia ra, he mea hanga hoki, mau tonu iho ai nga mea e kore nei e whakangaueuetia.
28 Nítorí náà bí àwa tí ń gbà ilẹ̀ ọba ti a kò lè mì, ẹ jẹ́ kí a dá ọpẹ́ nípa èyí ti a fi lè máa sin Ọlọ́run ni ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀lú ọ̀wọ̀ àti ìbẹ̀rù rẹ̀.
Na, ka riro nei i a tatou he kingitanga e kore e taea te whakangaueue, kia whiwhi tatou ki te aroha noa e manakohia mai ai ta tatou e mahi nei ki te Atua i runga i te hopohopo, i te wehi:
29 Nítorí pé, “Ọlọ́run wa, iná ti ń jó ni run ni.”
He ahi hoki e kai ana to tatou Atua.

< Hebrews 12 >