< Hebrews 12 >
1 Nítorí náà bí a ti fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ tí o kún fún àwọn ẹlẹ́rìí tó báyìí yí wa ká, ẹ jẹ́ kí a pa ohun ìdíwọ́ gbogbo tì sí apá kan, àti ẹ̀ṣẹ̀ tí o rọrùn láti di mọ́ wa, kí a sì máa fi sùúrù súré ìje tí a gbé ka iwájú wa,
Be amo dunu bagohame da ninima Gode Ea hou ba: su dunu esala. Amaiba: le, ninia da ilia hou defele, logo ga: su liligi huluane amola wadela: i hou amo da hedolowane nini bu la: gisa, amo huluane fadegamu da defea. Ninia hehenasu amo Gode da ninima olelei, amo mae yolesili ha: giwane hehenamu da defea.
2 kí a máa wo Jesu Olùpilẹ̀ṣẹ̀ àti aláṣepé ìgbàgbọ́ wa; ẹni nítorí ayọ̀ tí a gbé ka iwájú rẹ, tí o faradà àgbélébùú láìka ìtìjú sí, tí ó sì jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún ìtẹ́ Ọlọ́run.
Ninia mae beba: le, Yesu (ninia dafawaneyale dawa: su hou muni hemosu amola dagosu Ouligisu Dunu) amo fawane ba: mu da defea. E da bulufalegeiga bogomu dawa: beba: le, Ea hou hame yolesi. Be E da hahawane hou amoga doaga: musa: dawa: beba: le, bulufalegeiga bogomuba: le gogosiasu hou mae dawa: le, E da wali Gode Ea Hinadafa Fisu afodafa la: ididili fisa.
3 Máa ro ti ẹni tí ó faradà irú ìsọ̀rọ̀-òdì yìí láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ si ara rẹ̀, kí ẹ má ba á rẹ̀wẹ̀sì ni ọkàn yín, kí àárẹ̀ si mu yín.
Ea se nabasu dawa: ma! Wadela: i hamosu dunu da Ema nimiwane ha lai. Amaiba: le, dilia da da: i dioiba: le, dafawaneyale dawa: su hou yolesimu da defea hame.
4 Ẹ̀yin kò sá à tí ì kọ ojú ìjà si ẹ̀ṣẹ̀ títí dé títa ẹ̀jẹ̀ yín sílẹ̀ nínú ìjàkadì yín.
Dilia da wadela: i hou amoma gegenana. Be amoga dilia da hame medole legei ba: sa.
5 Ẹ̀yin sì ti gbàgbé ọ̀rọ̀ ìyànjú tí ó n ba yin sọ̀rọ̀ bí ọmọ pé, “Ọmọ mi, ma ṣe aláìnání ìbáwí Olúwa, kí o má sì ṣe rẹ̀wẹ̀sì nígbà tí a bá ń ti ọwọ́ rẹ̀ ba ọ wí,
Gode da ninima dogo denesima: ne “Na mano!” sia: sa. Dilia da amo sia: gogoleila: ? E da amane sia: sa, “Na mano! Hina Gode da dima dia hou hahamoma: ne sia: sea, Ea sia: nabima! E da dima gagabole sia: sea, mae da: i dioma!
6 nítorí pé ẹni ti Olúwa fẹ́, òun ni i bá wí, a sì máa na olúkúlùkù ọmọ tí òun tẹ́wọ́gbà.”
Bai Hina Gode da Ea dogolegei mano huluanema ilia hou hahamoma: ne sia: sa. Nowama E da ‘Na mano’ sia: sa, E da dawa: digima: ne se dabe iasu iaha!”
7 Ẹ máa ní sùúrù lábẹ́ ìbáwí, Ọlọ́run bá wa lò bí ọmọ ni; nítorí pé ọmọ wo ni ń bẹ ti baba kì í bá wí?
Dilia da se iasu nabasea, amo da ada ea hou agoane dilima maha dawa: beba: le, mae da: i dioma. Bai amo se nabasu da Gode da dili da Ea mano dawa: beba: le, agoane hamosa. Osobo bagade ada huluane da ilia manoma dawa: digima: ne se iasu iaha.
8 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin ba wà láìsí ìbáwí, nínú èyí tí gbogbo ènìyàn ti jẹ alábápín, ǹjẹ́ ọmọ àlè ni yín, ẹ kì í sì ṣe ọmọ.
Be dilia Gode Ea mano huluane amo defele ilia dawa: digima: ne se iasu laha hame ba: sea, amo dilia da manodafa hame be fa mano fawane esala olelesa.
9 Pẹ̀lúpẹ̀lú àwa ni baba wa nípa ti ara tí o ń tọ́ wa, àwa sì ń bu ọlá fún wọn: kò ha yẹ kí a kúkú tẹríba fún Baba àwọn ẹ̀mí, kí a sì yè?
Ninia osobo bagade ada da ninima se iasu iabeba: le, ninia bu beda: iwane ilima nodoi. Amaiba: le, ninia A: silibu Adadafa, Ema baligiliwane nabasu hou hamone, esalalalumu da defea.
10 Nítorí wọ́n tọ́ wa fún ọjọ́ díẹ̀ bí o bá ti dára lójú wọn; ṣùgbọ́n Òun tọ́ wa fún èrè wa, kí àwa lè ṣe alábápín ìwà mímọ́ rẹ̀.
Ninia osobo bagade ada, ilia hanaiba: le, eso bagahame amoga ninima se iasu. Be Gode da nini fidima: ne, nini Ea hadigi gilisili lama: ne, dawa: digima: ne se iasu iaha.
11 Gbogbo ìbáwí kò dàbí ohun ayọ̀ nísinsin yìí bí kò ṣe ìbànújẹ́; ṣùgbọ́n níkẹyìn yóò so èso àlàáfíà fún àwọn tí a tọ́ nípa rẹ̀, àní èso òdodo.
Ninia Gode Ea se iasu labeba: le, amo esoga hahawane hame gala, se naba. Be fa: no, amo se dabe iasu amoga ninia hou bu hahamoiba: le, hou ida: iwane bu lai dagoiba: le, ninia moloidafa olofosu hou bu fage agoane legelalu, Gode Ea se iasu bidi noga: i ba: mu.
12 Nítorí náà, ẹ na ọwọ́ tí ó rọ, àti eékún àìlera,
Amaiba: le, dilia lobo gaguia gadoma: ne amola dilia muguni yagugui gasa lama: ne, dogo denesima!
13 “Kí ẹ sì ṣe ipa ọ̀nà tí ó tọ́ fún ẹsẹ̀ yin,” kí èyí tí ó rọ má bá a kúrò lórí ike ṣùgbọ́n kí a kúkú wò ó sàn.
Fedege agoane, emo gasuga: igi dunu da mae dafane hahawane uhinisima: ne, logo moloidafa amoga fawane masa.
14 Ẹ máa lépa àlàáfíà pẹ̀lú ènìyàn gbogbo, àti ìwà mímọ́, láìsí èyí yìí kò sí ẹni tí yóò rí Olúwa.
Dunu huluanema olofosu hamoma: ne hogoi helema. Hadigi hame hamoi dunu da Hina Gode hamedafa ba: mu, amo dawa: beba: le, eso huluane hadigi hou hogoma.
15 Ẹ máa kíyèsára kí ẹnikẹ́ni má ṣe kùnà Oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run; kí gbòǹgbò ìkorò kan máa ba hù sókè kí ó sì yọ yín lẹ́nu, ọ̀pọ̀lọpọ̀ a sì ti ipa rẹ̀ di àìmọ́.
Dilia Gode Ea hahawane dogolegele iasu yolesili, beba: sa: besa: le, dawa: ma! Dunu afae da gamogai gisi agoane heda: le, bagadewane wili gala: le, dunu eno ilia hou wadela: mu da defea hame galebe.
16 Kí o má bá à si àgbèrè kan tàbí aláìwà-bí-Ọlọ́run bi Esau, ẹni tí o tìtorí òkèlè oúnjẹ kan ta ogún ìbí rẹ̀.
Dunu afae da wadela: i uda lasu hou o Iso agoane, a:silibu hou mae dawa: le, ha: i manu afadafa fawane hanaiba: le ea ada hobea magobo manoma nana imunu liligi huluane bidi lai dagoi, agoaiwane maedafa hamoma!
17 Nítorí ẹ̀yin mọ pé lẹ́yìn náà, nígbà tí ó fẹ́ láti jogún ìbùkún náà, a kọ̀ ọ́, nítorí kò ri ààyè ìrònúpìwàdà, bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ó fi omijé wa a gidigidi.
Iso da fa: no ea ada magobo manoma imunu nana liligi bu lamusa: dawa: i galu. E da dinanu, amo logo hogoi helele, be ea hou bu sinidigimusa: hamedei ba: beba: le, logo ga: si dagoi ba: i.
18 Nítorí ẹ̀yin kò wá òkè tí a lè fi ọwọ́ kàn, àti ti iná ti ń jó, àti ti ìṣúdudu àti òkùnkùn, àti ìjì.
Dilia da Isala: ili fi dunu defele, liligi gaguli ba: su dawa: liligi, amo Sainai Goumi laluga bagade nenanu, gasi bagade amola gulu bagebe alaloyo ganodini hamonanu, amo goumiga hame doaga: i.
19 Àti ìró ìpè, àti ohùn ọ̀rọ̀, èyí tí àwọn tí o gbọ́ bẹ̀bẹ̀ pé, kí a má ṣe sọ ọ̀rọ̀ sí i fún wọn mọ́,
Ilia da dalabede sia: amola sia: dafa nabi. Ilia amo sia: nabaloba, beda: iba: le bu mae nabima: ne ha: giwane edegei.
20 nítorí pé wọn kò lè gba ohun tí ó paláṣẹ, “Bí o tilẹ̀ jẹ ẹranko ni ó fi ara kan òkè náà, a ó sọ ọ́ ni òkúta.”
Bai ilia da sia: amo, “Dunu o ohe fi o eno liligi da goumi digili ba: sea fawane, ilia igiga medole legei dagoi ba: mu!” Ilia da amo sia: iba: le beda: ne, nabimu higa: i galu.
21 Ìran náà sì lẹ́rù to bẹ́ẹ̀ tí Mose wí pé, “Ẹ̀rù ba mi gidigidi mo sì wárìrì.”
Ba: su liligi da bogomuwane beda: ma: ne agoai galebe. Amaiba: le, Mousese da hi beda: iba: le amane sia: i, “Na da bagadewane beda: iba: le, yagugusa!”
22 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wá sí òkè Sioni, àti sí ìlú Ọlọ́run alààyè, ti Jerusalẹmu ti ọ̀run, àti si ẹgbẹ́ àwọn angẹli àìníye,
Be dilia da Saione Goumi amola Esalebe Gode Ea Moilai Bai Bagade amo Hebene ganodini gagui Yelusaleme (amo ganodini a: igele dunu osea: idafa esalebe ba: sa), amoga doaga: i dagoi.
23 si àjọ ńlá tí ìjọ àkọ́bí tí a ti kọ orúkọ wọn ni ọ̀run, àti sọ́dọ̀ Ọlọ́run onídàájọ́ gbogbo ènìyàn, àti sọ́dọ̀ àwọn ẹ̀mí olóòtítọ́ ènìyàn tí a ṣe ni àṣepé,
Dilia da Gode Ea degabo lalelegei mano amo ilia dio da Hebene ganodini dedei, amo ilia hahawane gilisisuma doaga: i dagoi. Dilia da Gode, amo da fifi asi gala dunu huluanema Fofada: su gala, amola noga: i dunu amo ilia a: silibu Gode da afadenene moloidafa hamoi dagoi, ilima doaga: i dagoi.
24 àti sọ́dọ̀ Jesu alárinà májẹ̀mú tuntun, àti si ibi ẹ̀jẹ̀ ìbùwọ́n ni, ti ń sọ̀rọ̀ ohun tí ó dára ju ti Abeli lọ.
Dilia da Yesu, amo da gaheabolo Gousa: su Sema hahamoi dagoi, amola maga: me fogaga: gala: i, amo Ea imunu liligi da A: ibele ea maga: me amo imunu hou baligisa, amoma doaga: i dagoi.
25 Kíyèsi i, kí ẹ má ṣe kọ̀ ẹni tí ń kìlọ̀. Nítorí bí àwọn wọ̀nyí kò bá bọ́ nígbà tí wọn kọ̀ ẹni ti ń kìlọ̀ ni ayé, mélòó mélòó ni àwa kì yóò bọ́, bí àwa ba pẹ̀yìndà sí ẹni tí ń kìlọ̀ láti ọ̀run wá,
Amaiba: le, dawa: ma! Sia: su dunu Ea sia: nabima: ne mae higama. Nowa da sisasu dunu e da osobo bagadega Gode sia: i liligi olelei, amo hame nabaloba, e da hobeale masunu logo hame ba: i. Amaiba: le, ninia Sisasu Dunu amo da Hebene amoga sia: sea, amo hame nabasea, hobeale masunu logo hamedafa ba: mu.
26 ohùn ẹni tí ó mi ayé nígbà náà, ṣùgbọ́n nísinsin yìí o ti ṣe ìlérí, wí pé, “Lẹ́ẹ̀kan sí i èmi ki yóò mi kìkì ayé nìkan, ṣùgbọ́n ọ̀run pẹ̀lú.”
Sisasu Dunu da musa: Ea sia: ga osobo bagade fawane ugugui. Be E da hobea hamoma: ne, amane sia: i, “Na da bu afadafa fawane eno, osobo bagade amola mu ugugumu!”
27 Àti ọ̀rọ̀ yìí, “Lẹ́ẹ̀kan sí i,” ìtumọ̀ rẹ̀ ni, mímú àwọn ohun wọ̀nyí ti a ń mì kúrò, bí ohun tí a ti dá, kí àwọn ohun tí a kò lè mì lè wà síbẹ̀.
E da “afadafa eno” sia: beba: le, amo hahamoi liligi da uguguli, mugululi, hamedafa ba: mu, amo ninia noga: le dawa: Be hame mugulumu dialumu liligi da amaiwane dialumu.
28 Nítorí náà bí àwa tí ń gbà ilẹ̀ ọba ti a kò lè mì, ẹ jẹ́ kí a dá ọpẹ́ nípa èyí ti a fi lè máa sin Ọlọ́run ni ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀lú ọ̀wọ̀ àti ìbẹ̀rù rẹ̀.
Amaiba: le, ninia da hobea Hinadafa Hou amo da mugulumu hamedei liligi, amo ba: musa: dawa: beba: le, ninia da Godema hahawaneba: le, E da nini hahawane ba: ma: ne, Ema beda: iwane nodomu da defea.
29 Nítorí pé, “Ọlọ́run wa, iná ti ń jó ni run ni.”
Bai ninia Gode da gugunufinisimusa: lalu agoane gala.