< Hebrews 11 >

1 Ǹjẹ́ ìgbàgbọ́ ní ìdánilójú ohun tí o ń retí, ìjẹ́rìí ohun tí a kò rí.
ⲁ̅ⲪⲚⲀϨϮ ⲆⲈ ⲞⲨⲦⲀϪⲢⲞ ⲠⲈ ⲚⲦⲈⲚⲎ ⲈⲦⲞⲨⲈⲢϨⲈⲖⲠⲒⲤ ⲈⲢⲰⲞⲨ ⲞⲨⲢⲈϤⲤⲞϨⲒ ⲠⲈ ⲚⲦⲈϨⲀⲚϨⲂⲎⲞⲨⲒ ⲚⲤⲈⲚⲀⲨ ⲈⲢⲰⲞⲨ ⲀⲚ.
2 Nítorí nínú rẹ ni àwọn alàgbà àtijọ́ ní ẹ̀rí rere.
ⲃ̅ϦⲈⲚ ⲪⲀⲒ ⲄⲀⲢ ⲀⲨⲈⲢⲘⲈⲐⲢⲈ ϦⲀ ⲚⲒⲠⲢⲈⲤⲂⲨⲦⲈⲢⲞⲤ.
3 Nípa ìgbàgbọ́ ni a mọ̀ pé a ti dá ayé nípa ọ̀rọ̀ Ọlọ́run; nítorí náà kì í ṣe ohun tí o hàn ni a fi dá ohun tí a ń ri. (aiōn g165)
ⲅ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲦⲈⲚⲔⲀϮ ϪⲈ ⲀⲨⲤⲞⲂϮ ⲚϪⲈⲚⲒⲈⲚⲈϨ ϦⲈⲚⲠⲤⲀϪⲒ ⲘⲪⲚⲞⲨϮ ϪⲈ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲚⲎ ⲈⲦⲈⲚⲤⲈⲞⲨⲞⲚϨ ⲈⲂⲞⲖ ⲀⲚ ⲀϤϢⲰⲠⲒ ⲚϪⲈⲪⲎ ⲈⲦⲞⲨⲚⲀⲨ ⲈⲢⲞϤ. (aiōn g165)
4 Nípa ìgbàgbọ́ ní Abeli rú ẹbọ sí Ọlọ́run tí ó sàn ju ti Kaini lọ, nípa èyí tí a jẹ́rìí rẹ̀ pe olódodo ni, Ọlọ́run sí ń jẹ́rìí ẹ̀bùn rẹ̀, àti nípa rẹ̀ náà, bí o ti jẹ́ pé o ti kú, síbẹ̀ o ń fọhùn.
ⲇ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲀⲂⲈⲖ ⲀϤⲈⲚ ϨⲞⲨⲞ ϢⲞⲨϢⲰⲞⲨϢⲒ ⲘⲪⲚⲞⲨϮ ⲈϨⲞⲦⲈ ⲔⲀⲒⲚ ⲪⲀⲒ ⲈⲦⲀⲨⲈⲢⲘⲈⲐⲢⲈ ϦⲀⲢⲞϤ ⲈⲂⲞⲖ ϨⲒⲦⲞⲦϤ ϪⲈ ⲞⲨⲐⲘⲎⲒ ⲠⲈ ⲈϤⲈⲢⲘⲈⲐⲢⲈ ⲚϪⲈⲪⲚⲞⲨϮ ⲈϨⲢⲎⲒ ⲈϪⲈⲚ ⲚⲈϤⲦⲀⲒⲞ ⲞⲨⲞϨ ⲈⲂⲞⲖ ϨⲒⲦⲞⲦϤ ⲈⲦⲀϤⲘⲞⲨ ϤⲤⲀϪⲒ ⲞⲚ.
5 Nípa ìgbàgbọ́ ni a ṣí Enoku ní ipò padà kí o má ṣe rí ikú; a kò sì rí i mọ́, nítorí Ọlọ́run ṣí i ní ipò padà ṣáájú ìṣípò padà rẹ̀, a jẹ́rìí yìí sí i pé o wu Ọlọ́run.
ⲉ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲈⲚⲰⲬ ⲀⲨⲞⲨⲞⲐⲂⲈϤ ⲈⲂⲞⲖ ⲈϢⲦⲈⲘⲚⲀⲨ ⲈⲪⲘⲞⲨ ⲞⲨⲞϨ ⲚⲀⲨϪⲒⲘⲒ ⲘⲘⲞϤ ⲀⲚ ⲠⲈ ϪⲈ ⲀⲪⲚⲞⲨϮ ⲞⲨⲞⲐⲂⲈϤ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲀϪⲰϤ ⲄⲀⲢ ⲘⲠⲒⲞⲨⲰⲦⲈⲂ ⲈⲂⲞⲖ ⲀⲨⲈⲢⲘⲈⲐⲢⲈ ϦⲀⲢⲞϤ ϪⲈ ⲀϤⲢⲀⲚⲀϤ ⲘⲪⲚⲞⲨϮ.
6 Ṣùgbọ́n láìsí ìgbàgbọ́ kò ṣe é ṣe láti wù ú; nítorí ẹni tí ó bá ń tọ Ọlọ́run wá kò lè ṣàì gbàgbọ́ pé ó ń bẹ, àti pé òun ní olùṣẹ̀san fún àwọn tí o fi ara balẹ̀ wá a.
ⲋ̅ⲀⲦϬⲚⲈ ⲚⲀϨϮ ⲆⲈ ⲘⲘⲞⲚ ϢϪⲞⲘ ⲈⲢⲀⲚⲀϤ ⲤϢⲈ ⲄⲀⲢ ⲚⲦⲈϤⲚⲀϨϮ ⲚϪⲈⲪⲎ ⲈⲐⲚⲎ ⲞⲨ ϨⲀ ⲪⲚⲞⲨϮ ϪⲈ ϤϢⲞⲠ ⲞⲨⲞϨ ϤⲚⲀϢⲰⲠⲒ ⲚⲢⲈϤϮⲂⲈⲬⲈ ⲚⲚⲎ ⲈⲦⲔⲰϮ ⲚⲤⲰϤ.
7 Nípa ìgbàgbọ́ ni Noa, nígbà ti Ọlọ́run, kìlọ̀ ohun tí a kóò tí ì rí fún un, o bẹ̀rù Ọlọ́run ó sì kan ọkọ̀ fún ìgbàlà ilé rẹ̀, nípa èyí tí ó da ayé lẹ́bi, ó sì di ajogún òdodo tí i ṣe nípa ìgbàgbọ́.
ⲍ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲚⲰⲈ ⲈⲦⲀⲨⲦⲀⲘⲞϤ ⲈⲐⲂⲈ ⲚⲎ ⲈⲦⲈ ⲘⲠⲀⲦⲞⲨⲚⲀⲨ ⲈⲢⲰⲞⲨ ⲀϤⲈⲢϨⲞϮ ⲀϤⲘⲞⲚⲔ ⲚⲞⲨⲔⲨⲂⲰⲦⲞⲤ ⲈⲨⲚⲞϨⲈⲘ ⲚⲦⲈⲠⲈϤⲎⲒ ⲐⲎ ⲈⲦⲀϤⲈⲢⲔⲀⲦⲀⲔⲢⲒⲚⲒⲚ ⲘⲠⲒⲔⲞⲤⲘⲞⲤ ⲈⲂⲞⲖ ϨⲒⲦⲞⲦⲤ ⲞⲨⲞϨ ⲀϤϢⲰⲠⲒ ⲚⲔⲖⲎⲢⲞⲚⲞⲘⲞⲤ ⲚⲦⲈϮⲘⲈⲐⲘⲎⲒ ⲚⲦⲈⲪⲚⲀϨϮ.
8 Nípa ìgbàgbọ́ ní Abrahamu, nígbà tí a ti pé e láti jáde lọ sí ibi tí òun yóò gbà fún ilẹ̀ ìní, ó gbọ́, ó sì jáde lọ, láì mọ ibi tí òun ń rè.
ⲏ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲪⲎ ⲈⲦⲞⲨⲘⲞⲨϮ ⲈⲢⲞϤ ϪⲈ ⲀⲂⲢⲀⲀⲘ ⲀϤⲤⲰⲦⲈⲘ ⲈⲒ ⲈⲂⲞⲖ ⲈⲠⲒⲘⲀ ⲈⲚⲀϤⲚⲀϬ ⲒⲦϤ ⲚⲔⲖⲎⲢⲞⲚⲞⲘⲒⲀ ⲞⲨⲞϨ ⲀϤⲒ ⲈⲂⲞⲖ ⲚϤⲈⲘⲒ ⲀⲚ ϪⲈ ⲀϤⲘⲞϢⲒ ⲈⲐⲰⲚ.
9 Nípa ìgbàgbọ́ ní o ṣe àtìpó ní ilẹ̀ ìlérí, bí ẹni pé ni ilẹ̀ àjèjì, o ń gbé inú àgọ́, pẹ̀lú Isaaki àti Jakọbu, àwọn ajogún ìlérí kan náà pẹ̀lú rẹ̀,
ⲑ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲀϤⲈⲢⲢⲈⲘⲚϪⲰⲒⲖⲒ ϦⲈⲚⲠⲔⲀϨⲒ ⲚⲦⲈϮⲈⲠⲀⲄⲄⲈⲖⲒⲀ ϨⲰⲤ ⲘⲪⲰϤ ⲀⲚ ⲠⲈ ⲈⲀϤϢⲰⲠⲒ ϦⲈⲚϨⲀⲚⲤⲔⲎⲚⲎ ⲚⲈⲘ ⲒⲤⲀⲀⲔ ⲚⲈⲘ ⲒⲀⲔⲰⲂ ⲚⲒϢⲪⲎⲢ ⲚⲔⲖⲎⲢⲞⲚⲞⲘⲞⲤ ⲚⲦⲈⲠⲀⲒⲰϢ ⲢⲰ.
10 nítorí tí ó ń retí ìlú tí ó ní ìpìlẹ̀; èyí tí Ọlọ́run tẹ̀dó tí ó sì kọ́.
ⲓ̅ⲚⲀϤϪⲞⲨϢⲦ ⲄⲀⲢ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲀⲦϨⲎ ⲚϮⲂⲀⲔⲒ ⲐⲎ ⲈⲦⲈ ⲞⲨⲞⲚⲦⲀⲤ ⲚⲚⲒⲤⲈⲚϮ ⲘⲘⲀⲨ ⲐⲎ ⲈⲦⲈ ⲠⲈⲤⲦⲈⲬⲚⲒⲦⲎⲤ ⲚⲈⲘ ⲠⲈⲤⲢⲈϤⲐⲀⲘⲒⲞ ⲠⲈ ⲪⲚⲞⲨϮ.
11 Nípa ìgbàgbọ́ ni Sara tìkára rẹ̀ pẹ̀lú fi gba agbára láti lóyún, nígbà tí ó kọjá ìgbà rẹ̀, nítorí tí o ka ẹni tí o ṣe ìlérí sí olóòótọ́.
ⲓ̅ⲁ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲚⲐⲞⲤ ϨⲰⲤ ⲤⲀⲢⲢⲀ ϮⲀϬⲢⲎⲚ ⲀⲤϬⲒ ⲚⲞⲨϪⲞⲘ ⲈⲠⲦⲀⲞⲨⲞ ⲈⲂⲞⲖ ⲚⲦⲈⲞⲨϪⲢⲞϪ ⲞⲨⲞϨ ⲚⲈⲠⲤⲎⲞⲨ ⲀⲚ ⲠⲈ ⲚⲦⲈⲦⲈⲤⲘⲀⲒⲎ ⲈⲠⲒⲆⲎ ⲀϤϢⲰⲠⲒ ⲈϤⲈⲚϨⲞⲦ ⲚⲦⲞⲦⲤ ⲚϪⲈⲪⲎ ⲈⲦⲀϤⲰϢ.
12 Nítorí náà ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣe ti ara ọkùnrin kan jáde, àní ara ẹni tí o dàbí òkú, ọmọ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run lọ́pọ̀lọ́pọ̀, àti bí iyanrìn etí Òkun láìníye.
ⲓ̅ⲃ̅ⲈⲐⲂⲈⲪⲀⲒ ⲀⲨⲘⲀⲤⲞⲨ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲞⲨⲀⲒ ⲔⲈ ⲦⲀⲨⲦⲀ ⲈⲀϤⲰϪϤ ⲚϪⲈⲠⲒⲤⲰⲘⲀ ⲔⲀⲦⲀ ⲪⲢⲎϮ ⲚⲚⲒⲤⲒⲞⲨ ⲚⲦⲈⲦⲪⲈ ϦⲈⲚⲠⲞⲨⲀϢⲀⲒ ⲚⲈⲘ ⲘⲪⲢⲎϮ ⲘⲠⲒϢⲰ ⲈⲦϦⲀⲦⲈⲚ ⲚⲈⲚⲤⲪⲞⲦⲞⲨ ⲘⲪⲒⲞⲘ ⲈⲦⲈ ⲘⲠⲀⲨϬⲒⲎⲠⲒ ⲘⲘⲞϤ.
13 Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ó kú nínú ìgbàgbọ́, láìrí àwọn ìlérí náà gbà, ṣùgbọ́n tí wọn rí wọn ni òkèrè réré, tí wọ́n sì gbá wọn mú, tí wọ́n sì jẹ́wọ́ pé àlejò àti àjèjì ni àwọn lórí ilẹ̀ ayé.
ⲓ̅ⲅ̅ⲔⲀⲦⲀ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲚⲀⲒ ⲦⲎⲢⲞⲨ ⲀⲨⲘⲞⲨ ⲘⲠⲞⲨϬⲒ ⲚⲚⲒⲈⲠⲀⲄⲄⲈⲖⲒⲀ ⲀⲖⲖⲀ ⲀⲨⲚⲀⲨ ⲈⲢⲰⲞⲨ ϨⲒⲪⲞⲨⲈⲒ ⲞⲨⲞϨ ⲀⲨⲈⲢⲀⲤⲠⲀⲌⲈⲤⲐⲈ ⲘⲘⲰⲞⲨ ⲞⲨⲞϨ ⲀⲨⲞⲨⲞⲚϨ ⲈⲂⲞⲖ ϪⲈ ϨⲀⲚϢⲈⲘⲘⲰⲞⲨ ⲚⲈⲞⲨⲞϨ ⲚⲢⲈⲘⲚϪⲰⲒⲖⲒ ϨⲒϪⲈⲚ ⲠⲒⲔⲀϨⲒ.
14 Nítorí pé àwọn tí o ń sọ irú ohun bẹ́ẹ̀ fihàn gbangba pé, wọn ń ṣe àfẹ́rí ìlú kan tí i ṣe tiwọn.
ⲓ̅ⲇ̅ⲚⲎ ⲄⲀⲢ ⲈⲦϪⲰ ⲚⲚⲀⲒ ⲘⲠⲀⲒⲢⲎϮ ⲤⲈⲞⲨⲞⲚϨ ⲈⲂⲞⲖ ϪⲈ ⲀⲨⲔⲰϮ ⲚⲤⲀⲞⲨⲂⲀⲔⲒ ⲚⲦⲈⲞⲨⲘⲀ ⲚϢⲰⲠⲒ.
15 Àti nítòótọ́, ìbá ṣe pé wọ́n fi ìlú tiwọn tí jáde wá sí ọkàn, wọn ìbá ti rí ààyè padà.
ⲓ̅ⲉ̅ⲞⲨⲞϨ ⲒⲤϪⲈ ⲘⲈⲚ ⲚⲀⲨⲒⲢⲒ ⲘⲪⲘⲈⲨⲒ ⲚⲐⲎ ⲈⲦⲀⲨⲒ ⲈⲂⲞⲖ ⲚϦⲎⲦⲤ ⲒⲈ ⲚⲈⲞⲨⲞⲚⲦⲞⲨ ⲤⲎⲞⲨ ⲠⲈ ⲈⲦⲀⲤⲐⲞ ⲈⲢⲞⲤ.
16 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n ń fẹ́ ìlú kan tí o dára jù bẹ́ẹ̀ lọ, èyí yìí ni ti ọ̀run, nítorí náà ojú wọn kò ti Ọlọ́run, pé kí a máa pé òun ni Ọlọ́run wọn; nítorí tí o ti pèsè ìlú kan sílẹ̀ fún wọn.
ⲓ̅ⲋ̅ϮⲚⲞⲨ ⲆⲈ ⲤⲈⲈⲢⲈⲠⲒⲐⲨⲘⲒⲚ ⲈⲐⲎ ⲈⲦⲤⲞⲦⲠ ⲚϨⲞⲨⲞ ⲈⲦⲈ ⲐⲀ ⲦⲪⲈ ⲦⲈ ⲈⲐⲂⲈⲪⲀⲒ ⲚϤϢⲒⲠⲒ ⲘⲘⲰⲞⲨ ⲀⲚ ⲚϪⲈⲪⲚⲞⲨϮ ⲈⲐⲢⲞⲨⲘⲞⲨϮ ⲈⲢⲞϤ ⲚⲚⲞⲨϮ ⲚⲰⲞⲨ ⲀϤⲤⲞⲂϮ ⲄⲀⲢ ⲚⲰⲞⲨ ⲚⲞⲨⲂⲀⲔⲒ.
17 Nípa ìgbàgbọ́ ni Abrahamu, nígbà tí a dán an wò láti, fi Isaaki rú ẹbọ: àní òun ẹni tí ó rí ìlérí gba múra tan láti fi ọmọ bíbí rẹ kan ṣoṣo rú ẹbọ.
ⲓ̅ⲍ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲀⲂⲢⲀⲀⲘ ⲀϤⲒⲚⲒ ⲚⲒⲤⲀⲀⲔ ⲈϨⲢⲎⲒ ⲈⲨⲈⲢⲠⲒⲢⲀⲌⲒⲚ ⲘⲘⲞϤ ⲀϤⲒⲚⲒ ⲘⲠⲈϤϢⲎ ⲢⲒ ⲘⲘⲀⲨⲀⲦϤ ⲈϨⲢⲎⲒ ⲚϪⲈⲪⲎ ⲈⲦⲀϤϢⲈⲠ ⲚⲒⲰϢ ⲈⲢⲞϤ
18 Nípa ẹni tí wí pé, “Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀.”
ⲓ̅ⲏ̅ⲪⲎ ⲈⲦⲀⲨⲤⲀϪⲒ ⲚⲈⲘⲀϤ ϪⲈ ϦⲈⲚⲒⲤⲀⲀⲔ ⲈⲨⲈⲐⲀϨⲈⲘ ⲞⲨϪⲢⲞϪ ⲚⲀⲔ.
19 Ó sì rò ó si pé Ọlọ́run tilẹ̀ lè gbé e dìde kúrò nínú òkú, bẹ́ẹ̀ ni, bí a bá sọ ọ́ lọ́nà àpẹẹrẹ, ó gbà á padà.
ⲓ̅ⲑ̅ⲞⲨⲞϨ ⲀϤⲘⲞⲔⲘⲈⲔ ϪⲈ ⲞⲨⲞⲚ ϢϪⲞⲘ ⲘⲪⲚⲞⲨϮ ⲈⲦⲞⲨⲚⲞⲤϤ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲚⲎ ⲈⲐⲘⲰⲞⲨⲦ ⲈⲐⲂⲈⲪⲀⲒ ⲀϤϬⲒⲦϤ ϦⲈⲚⲞⲨⲠⲀⲢⲀⲂⲞⲖⲎ.
20 Nípa ìgbàgbọ́ ní Isaaki súre fún Jakọbu àti Esau ní ti ohun tí ń bọ̀.
ⲕ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲈⲐⲂⲈ ⲚⲎ ⲈⲐⲚⲀϢⲰⲠⲒ ⲀϤⲤⲘⲞⲨ ⲚϪⲈⲒⲤⲀⲀⲔ ⲈⲒⲀⲔⲰⲂ ⲚⲈⲘ ⲎⲤⲀⲨ.
21 Nípa ìgbàgbọ́ ni Jakọbu, nígbà tí o ń ku lọ, ó súre fún àwọn ọmọ Josẹfu ni ọ̀kọ̀ọ̀kan; ó sì sinmi ní ìtẹríba lé orí ọ̀pá rẹ̀.
ⲕ̅ⲁ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲒⲀⲔⲰⲂ ⲈϤⲚⲀⲘⲞⲨ ⲀϤⲤⲘⲞⲨ ⲈⲪⲞⲨⲀⲒ ⲪⲞⲨⲀⲒ ⲚⲚⲈⲚϢⲎⲢⲒ ⲚⲒⲰⲤⲎⲪ ⲞⲨⲞϨ ⲀϤⲞⲨⲰϢⲦ ⲈϪⲈⲚ ϨⲐⲎϤ ⲘⲠⲈϤϢⲪⲰⲦ.
22 Nípa ìgbàgbọ́ ni Josẹfu, nígbà tí ó ń ku lọ, ó rántí ìjáde lọ àwọn ọmọ Israẹli; ó sì pàṣẹ ní ti àwọn egungun rẹ̀.
ⲕ̅ⲃ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲒⲰⲤⲎⲪ ⲈϤⲚⲀⲘⲞⲨ ⲀϤⲈⲢⲪⲘⲈⲨⲒ ⲘⲠϪⲒⲚⲒ ⲈⲂⲞⲖ ⲚⲚⲈⲚϢⲎⲢⲒ ⲘⲠⲒⲤⲖ ⲞⲨⲞϨ ⲀϤϨⲞⲚϨⲈⲚ ⲈⲐⲂⲈ ⲚⲈϤⲔⲀⲤ.
23 Nípa ìgbàgbọ́ ní àwọn òbí Mose pa a mọ́ fún oṣù mẹ́ta nígbà tí a bí i, nítorí tiwọn rí i ní arẹwà ọmọ; wọn kò sì bẹ̀rù àṣẹ ọba.
ⲕ̅ⲅ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲘⲰⲨⲤⲎⲤ ⲈⲦⲀⲨⲘⲀⲤϤ ⲀⲨⲬⲞⲠϤ ⲚⲄ ⲚⲀⲂⲞⲦ ⲚϪⲈⲚⲈϤⲒⲞϮ ϪⲈ ⲀⲨⲚⲀⲨ ⲈⲠⲒⲀⲖⲞⲨ ϪⲈ ⲞⲨⲀⲤⲦⲒⲞⲤ ⲠⲈ ⲞⲨⲞϨ ⲘⲠⲞⲨⲈⲢϨⲞϮ ϦⲀⲦϨⲎ ⲘⲠⲒϨⲰⲠ ⲚⲦⲈⲠⲞⲨⲢⲞ.
24 Nípa ìgbàgbọ́ ni Mose, nígbà tí o dàgbà, ó kọ̀ ki a máa pé òun ni ọmọ ọmọbìnrin Farao;
ⲕ̅ⲇ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲘⲰⲨⲤⲎⲤ ⲈⲦⲀϤⲈⲢⲚⲒϢϮ ⲀϤϪⲰⲖ ⲈⲂⲞⲖ ⲈϢⲦⲈⲘⲈⲐⲢⲞⲨⲘⲞⲨϮ ⲈⲢⲞϤ ϪⲈ ⲠϢⲎⲢⲒ ⲚⲦϢⲈⲢⲒ ⲘⲪⲀⲢⲀⲰ.
25 o kúkú yàn láti máa ba àwọn ènìyàn Ọlọ́run jìyà, ju jíjẹ fàájì ẹ̀ṣẹ̀ fún ìgbà díẹ̀.
ⲕ̅ⲉ̅ⲘⲀⲖⲖⲞⲚ ⲈⲀϤⲞⲨⲰϢ ⲈϢⲈⲠⲘⲔⲀϨ ⲚⲈⲘ ⲠⲒⲖⲀⲞⲤ ⲚⲦⲈⲪⲚⲞⲨϮ ⲈϨⲞⲦⲈ ⲚⲦⲈϤϬⲒⲘⲎ ϦⲈⲚⲪⲚⲞⲂⲒ ⲠⲢⲞⲤ ⲞⲨⲤⲎⲞⲨ.
26 Ó ka ẹ̀gàn Kristi si ọrọ̀ tí ó pọ̀jù àwọn ìṣúra Ejibiti lọ, nítorí tí ó ń wo èrè náà.
ⲕ̅ⲋ̅ⲈⲀϤⲬⲀ ⲠϢⲰϢ ⲘⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ ⲚⲦⲞⲦϤ ϪⲈ ⲞⲨⲘⲈⲦⲢⲀⲘⲀⲞ ⲈⲚⲀⲀⲤ ⲦⲈ ⲈϨⲞⲦⲈ ⲚⲒⲀϨⲰⲢ ⲚⲦⲈⲬⲎⲘⲒ ⲈⲚⲀϤϪⲞⲨϢⲦ ⲄⲀⲢ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲀⲦϨⲎ ⲘⲠⲒϢⲈⲂⲒⲈ ⲂⲈⲬⲈ.
27 Nípa ìgbàgbọ́ ni o kọ Ejibiti sílẹ̀ láìbẹ̀rù ìbínú ọba: nítorí tí o dúró ṣinṣin bí ẹni tí ó n ri ẹni àìrí.
ⲕ̅ⲍ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲀϤⲬⲀ ⲬⲎⲘⲒ ⲚⲤⲰϤ ⲘⲠⲈϤⲈⲢϨⲞϮ ϦⲀⲦϨⲎ ⲘⲠⲒⲘⲂⲞⲚ ⲚⲦⲈⲠⲞⲨⲢⲞ ⲠⲒⲀⲐⲚⲀⲨ ⲄⲀⲢ ⲈⲢⲞϤ ⲚⲀϤⲘⲞⲨⲚ ⲈⲢⲞϤ ⲘⲪⲢⲎϮ ⲚⲞⲨⲀⲒ ⲈϤⲚⲀⲨ ⲈⲢⲞϤ.
28 Nípa ìgbàgbọ́ ni ó da àsè ìrékọjá sílẹ̀, àti ìbùwọ́n ẹ̀jẹ̀, kí ẹni tí ń pa àwọn àkọ́bí ọmọ má bá a fi ọwọ́ kan wọn.
ⲕ̅ⲏ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲀϤⲒⲢⲒ ⲘⲠⲒⲠⲀⲤⲬⲀ ⲚⲈⲘ ⲠⲒⲪⲰⲚ ⲈⲂⲞⲖ ⲚⲦⲈⲠⲒⲤⲚⲞϤ ϨⲒⲚⲀ ⲚⲦⲈϢⲦⲈⲘ ⲠⲒⲢⲈϤⲦⲀⲔⲞ ϬⲒ ⲚⲈⲘ ⲚⲞⲨϢⲞⲢⲠ ⲘⲘⲒⲤⲒ.
29 Nípa ìgbàgbọ́ ni wọn la òkun pupa kọjá bi ẹni pé ni ìyàngbẹ ilẹ̀ ni: ti àwọn ara Ejibiti dánwò, tí wọ́n sì ri.
ⲕ̅ⲑ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲀⲨⲤⲒⲚⲒ ⲈⲂⲞⲖ ϨⲒⲦⲈⲚ ⲪⲒⲞⲘ ⲚϢⲀⲢⲒ ⲘⲪⲢⲎϮ ⲚⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲞⲨⲔⲀϨⲒ ⲈϤϢⲞⲨⲰⲞⲨ ⲪⲎ ⲈⲦⲀⲨϬⲒⲠⲒⲢⲀ ⲚϦⲎⲦϤ ⲚϪⲈⲚⲒⲢⲈⲘⲚⲬⲎ ⲘⲒ ⲀⲨⲰⲘⲤ ⲈϦⲢⲎⲒ.
30 Nípa ìgbàgbọ́ ni àwọn odi Jeriko wo lulẹ̀, lẹ́yìn ìgbà tí a yí wọn ká ni ọjọ́ méje.
ⲗ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲚⲒⲤⲞⲂⲦ ⲚⲦⲈⲒⲈⲢⲒⲬⲰ ⲀⲨϨⲈⲒ ⲈⲦⲀⲨⲔⲰϮ ⲈⲢⲰⲞⲨ ⲚⲌ ⲚⲈϨⲞⲞⲨ.
31 Nípa ìgbàgbọ́ ni Rahabu panṣágà kò ṣègbé pẹ̀lú àwọn tí kò gbọ́rọ̀ nígbà tí o tẹ́wọ́gbà àwọn àmì ní àlàáfíà.
ⲗ̅ⲁ̅ϦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲢⲀⲀⲂ ϮⲠⲞⲢⲚⲎ ⲘⲠⲈⲤⲦⲀⲔⲞ ⲚⲈⲘ ⲚⲎ ⲈⲦⲀⲨⲈⲢⲀⲦⲤⲰⲦⲈⲘ ⲈⲦⲀⲤϢⲎ ⲠⲚⲒϪⲎⲢ ⲈⲢⲞⲤ ϦⲈⲚⲞⲨϨⲒⲢⲎⲚⲎ.
32 Èwo ni èmi o sì tún máa wí sí i? Nítorí pé ìgbà yóò kùnà fún mi láti sọ ti Gideoni, àti Baraki, àti Samsoni, àti Jefta; àti Dafidi, àti Samuẹli, àti ti àwọn wòlíì,
ⲗ̅ⲃ̅ⲞⲨⲞϨ ⲚⲦⲀϪⲞⲤ ⲞⲚ ϪⲈ ⲞⲨ ⲈϤⲈⲘⲞⲨⲚⲔ ⲄⲀⲢ ⲈⲢⲞⲒ ⲚϪⲈⲠⲒⲤⲎⲞⲨ ⲈⲒⲪⲒⲢⲒ ⲈⲐⲂⲈ ⲄⲈⲆⲈⲰⲚ ⲂⲀⲢⲀⲔ ⲤⲀⲘⲮⲰⲘ ⲒⲈⲪⲐⲀⲒⲈ ⲆⲀⲨⲒⲆ ⲚⲈⲘ ⲤⲀⲘⲞⲨⲎⲖ ⲚⲈⲘ ⲚⲒⲔⲈⲠⲢⲞⲪⲎⲦⲎⲤ.
33 àwọn ẹni nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ tiwọn ṣẹ́gun ilẹ̀ ọba, tí wọn ṣiṣẹ́ òdodo, tiwọn gba ìlérí, tiwọn dí àwọn kìnnìún lénu,
ⲗ̅ⲅ̅ⲚⲎ ⲈⲦⲈ ⲈⲂⲞⲖ ϨⲒⲦⲈⲚ ⲞⲨⲚⲀϨϮ ⲀⲨϬⲢⲞ ⲈϨⲀⲚⲘⲈⲦⲞⲨⲢⲰⲞⲨ ⲀⲨⲈⲢϨⲰⲂ ⲈϮⲘⲈⲐⲘⲎ ⲒⲀ ⲦⲞⲦⲞⲨ ϬⲒ ⲚⲚⲒⲰϢ ⲀⲨⲐⲰⲘ ⲚⲢⲰⲞⲨ ⲚϨⲀⲚⲘⲞⲨⲒ.
34 tí wọ́n pa agbára iná, tí wọ́n bọ́ lọ́wọ́ ojú idà, tí a sọ di alágbára nínú àìlera, tí wọ́n dí akọni nínú ìjà, wọ́n lé ogun àwọn àjèjì sá.
ⲗ̅ⲇ̅ⲀⲨⲰϢⲈⲘ ⲈⲦϪⲞⲘ ⲚⲦⲈⲞⲨⲬⲢⲰⲘ ⲀⲨⲪⲰⲦ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲢⲰⲞⲨ ⲚϨⲀⲚⲤⲎϤⲒ ⲀⲨϪⲈⲘϪⲞⲘ ϦⲈⲚⲠϢⲰⲚⲒ ⲀⲨϢⲰⲠⲒ ⲈⲨϪⲞⲢ ϦⲈⲚⲠⲒⲠⲞⲖⲈⲘⲞⲤ ⲀⲨⲢⲒⲔⲒ ⲚϨⲀⲚⲠⲀⲢⲈⲘⲂⲞⲖⲎ ⲚⲦⲈϨⲀⲚϢⲈⲘⲘⲰⲞⲨ.
35 Àwọn obìnrin ri òkú wọn gbà nípa àjíǹde: a sì da àwọn ẹlòmíràn lóró, wọ́n kọ̀ láti gba ìdásílẹ̀; kí wọn ba lè rí àjíǹde tí o dára jù gbà.
ⲗ̅ⲉ̅ⲀⲨϬⲒ ⲚϪⲈϨⲀⲚϨⲒⲞⲘⲒ ⲚⲚⲞⲨⲢⲈϤⲘⲰⲞⲨⲦ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲞⲨⲀⲚⲀⲤⲦⲀⲤⲒⲤ ϨⲀⲚⲔⲈⲬ ⲰⲞⲨⲚⲒ ⲀⲨⲞⲨⲈϢⲞⲨⲰϢⲞⲨ ⲘⲪⲢⲎϮ ⲚϨⲀⲚⲔⲈⲘⲔⲈⲘ ⲘⲠⲞⲨϢⲈⲠ ⲠⲒⲤⲰϮ ⲈⲢⲰⲞⲨ ϨⲒⲚⲀ ⲚⲦⲈⲦⲞⲦⲞⲨ ϬⲒ ⲚϮⲀⲚⲀⲤⲦⲀⲤⲒⲤ ⲈⲦⲤⲞⲦⲠ.
36 Àwọn ẹlòmíràn sì rí ìjìyà ẹ̀sín, àti nínà, àti ju bẹ́ẹ̀ lọ, ti ìdè àti ti túbú.
ⲗ̅ⲋ̅ϨⲀⲚⲔⲈⲬⲰⲞⲨⲚⲒ ⲆⲈ ϦⲈⲚϨⲀⲚⲤⲰⲂⲒ ⲚⲈⲘ ϨⲀⲚⲘⲈⲤⲦⲒⲄⲄⲞⲤ ⲀⲨϬⲒⲠⲒⲢⲀ ⲈⲦⲒ ⲆⲈ ⲚⲈⲘ ϨⲀⲚⲔⲈⲤⲚⲀⲨϨ ⲚⲈⲘ ϨⲀⲚϢⲦⲈⲔⲰⲞⲨ.
37 A sọ wọ́n ni òkúta, a fi ayùn rẹ́ wọn sì méjì, a dán wọn wò a fi idà pa wọn, wọ́n rìn káàkiri nínú awọ àgùntàn àti nínú awọ ewúrẹ́; wọn di aláìní, olùpọ́njú, ẹni tí a ń da lóró;
ⲗ̅ⲍ̅ⲀⲨϨⲒⲰⲚⲒ ⲈϪⲰⲞⲨ ⲀⲨⲂⲀⲤⲞⲨ ⲚⲐⲂⲀϢⲞⲨⲢ ⲀⲨⲈⲢⲠⲒⲢⲀⲌⲒⲚ ⲘⲘⲰⲞⲨ ⲀⲨⲘⲞⲨ ϦⲈⲚⲠϦⲰⲦⲈⲂ ⲚⲦⲤⲎϤⲒ ⲀⲨⲘⲞϢⲒ ϦⲈⲚϨⲀⲚⲘⲈⲖⲰⲦⲎ ϦⲈⲚϨⲀⲚϢⲀⲢ ⲘⲂⲀⲈⲘⲠⲒ ⲈⲨⲈⲢϦⲀⲈ ⲈⲨϨⲈϪϨⲰϪ ⲈⲨϬⲒⲘⲔⲀϨ.
38 àwọn ẹni tí ayé ko yẹ fún. Wọ́n ń kiri nínú aṣálẹ̀, àti lórí òkè, àti nínú ihò àti nínú abẹ́ ilẹ̀.
ⲗ̅ⲏ̅ⲚⲀⲒ ⲈⲦⲈ ⲚⲀⲢⲈ ⲠⲒⲔⲞⲤⲘⲞⲤ ⲘⲠϢⲀ ⲘⲘⲰⲞⲨ ⲀⲚ ⲠⲈ ⲈⲨⲤⲰⲢⲈⲘ ϨⲒ ⲚⲒϢⲀϤⲈⲨ ⲚⲈⲘ ⲚⲒⲦⲰⲞⲨ ⲚⲈⲘ ⲚⲒⲂⲎⲂ ⲚⲈⲘ ⲚⲒⲬⲞⲖ ⲚⲦⲈⲠⲔⲀϨⲒ.
39 Gbogbo àwọn wọ̀nyí tí a jẹ́rìí rere sí nípa ìgbàgbọ́, wọn kò sì rí ìlérí náà gbà,
ⲗ̅ⲑ̅ⲞⲨⲞϨ ⲚⲀⲒ ⲦⲎⲢⲞⲨ ⲈⲦⲀⲨⲈⲢⲘⲈⲐⲢⲈ ϦⲀⲢⲰⲞⲨ ⲈⲂⲞⲖ ϨⲒⲦⲈⲚ ⲠⲒⲚⲀϨϮ ⲘⲠⲞⲨϬⲒ ⲘⲠⲒⲰϢ.
40 nítorí Ọlọ́run ti pèsè ohun tí ó dára jù sílẹ̀ fún wa, pé láìsí wa, kí a má ṣe wọn pé.
ⲙ̅ⲈⲀϤϪⲞⲨϢⲦ ⲒⲤϪⲈⲚ ϢⲞⲢⲠ ⲚϪⲈⲪⲚⲞⲨϮ ϦⲀⲦϨⲎ ⲚⲞⲨϨⲰⲂ ⲈϤⲤⲞⲦⲠ ⲈⲐⲂⲎⲦⲈⲚ ϨⲒⲚⲀ ⲚⲤⲈϢⲦⲈⲘϪⲰⲔ ⲈⲂⲞⲖ ⲀⲦϬⲚⲞⲨⲚ.

< Hebrews 11 >