< Hebrews 10 >

1 Nítorí tí òfin jẹ́ òjìji àwọn ohun rere ti ń bọ̀ tí kì í ṣe àwòrán tòótọ́ fún àwọn òtítọ́ náà, wọn kò lè fi ẹbọ kan náà tí wọn ń rú nígbà gbogbo lọ́dọọdún mu àwọn tí ń wá jọ́sìn di pípé.
Jehudi Hootthe ah tah khomka eno amiisak angla rah erah laaphaang; erah ese ah dong suh heh laaphaang ah ban noisok ha. Phoosiitsiit romhoon ah saarookwe hoonha, paang siit ang leh hoon. Erah Hootthe jun ih Rangte reeni wangte mina loong ah arah romhoon jun ih mamah ma jen punsiit ah?
2 Bí kò ṣe bẹ́ẹ̀, a kì ìbá tí dẹ́kun àti máa rú wọn, nítorí àwọn ti ń sìn ki ìbá tí ní ìmọ̀ ẹ̀ṣẹ̀, nígbà tí a bá ti wẹ̀ wọ́n mọ́ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Mina loong Rangte khorongngot rangsoom nawa ih neng rangdah ah mok jen saahaat rumta bah, neng rangdah asuh ethih ngeh takah li rum thengta, khojoop hoon ah thinhaat erum thengta.
3 Ṣùgbọ́n nínú ẹbọ wọ̀nyí ni a ń ṣe ìrántí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́dọọdún.
Emamah ih hepaang rookwe khojoop rumta rah ih neng rangdah loong rah woot dokthun thuk rumha.
4 Nítorí ko ṣe é ṣe fún ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù àti ti ewúrẹ́ láti mú ẹ̀ṣẹ̀ kúrò.
Mamah liidih maan nyia ki sih loong rah ih timtok doh uh rangdah ah tajen dok haatta.
5 Nítorí náà nígbà tí Kristi wá sí ayé, ó wí pé, “Ìwọ kò fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ, ṣùgbọ́n ara ni ìwọ ti pèsè fún mi,
Erah raangtaan ih, Kristo ah mongrep ni eraak nanah dih heh ih Rangte suh baatta: “Khojoop siik hoon ah an ih takah jam ko ang uh, enoothong nga raangtaan ih sak esiit ban khookhamtu.
6 ẹbọ sísun àti ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ ni ìwọ kò ní inú dídùn sí.
Romthong ni huiawak sook ha suh nyia rangdah dok haat raangtaan ih khojoop ha suh an taroon ko.
7 Nígbà náà ni mo wí pé, ‘Kíyèsi i (nínú ìwé kíká ni a gbé kọ ọ́ nípa ti èmi) mo dé láti ṣe ìfẹ́ rẹ, Ọlọ́run.’”
Eno ngah ih baattang, O Rangte, an thung jun ih re suh, ‘Ngah aani’ Hootthe leedap ni nga raang ih raangha likhiikkhiik ah.’”
8 Nígbà tí o wí ni ìṣáájú pé, “Ìwọ kò fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ àti ẹbọ sísun, àti ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò ni inú dídùn si wọn” (àwọn èyí tí a ń rú gẹ́gẹ́ bí òfin).
Jaakhoh phangbaatta ah, “Khojoop siik hoon suh nyia rangdah dok haat suh luiamaan sook ano kot ah tah jamko edoleh tah roonko.” Heh ih emah laang jengta bah uh Hootthe jun ih khojoop siik hoon ah hoon ruh erumta.
9 Nígbà náà ni ó wí pé, “Kíyèsi i, mo de láti ṣe ìfẹ́ rẹ Ọlọ́run.” Ó mú ti ìṣáájú kúrò, kí a lè fi ìdí èkejì múlẹ̀.
Eno heh ih liita, “O Rangte, an thung jundoh re suh ngah aani.” Eno ehak khojoop ah Rangte ih dok haat ano Kristo khojoop ah weelek thinta.
10 Nípa ìfẹ́ náà ni a ti sọ wá di mímọ́ nípa ẹbọ ti Jesu Kristi fi ara rẹ̀ rú lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Mamah liidih Jisu Kristo ah Rangte thung jun ih reeta, erah jaasiit saarookwe raangtaan ih heh sak tek haat raangtaan ih seng loong ah seng rangdah nawa esa eti.
11 Àti olúkúlùkù àlùfáà sì ń dúró lójoojúmọ́ láti ṣiṣẹ́ ìsìn, ó sì ń ṣe ẹbọ kan náà nígbàkígbà, tí kò lè mú ẹ̀ṣẹ̀ kúrò láé.
Jehudi romwah ih saarookwe heh moot ah mota eno erarah khojoop ah jaarook we kahoonta; enoothong erah khojoop siik hoon rah ih tim saadoh uh rangdah ah tah sa haatka.
12 Ṣùgbọ́n òun, lẹ́yìn ìgbà tí o ti rú ẹbọ kan fún ẹ̀ṣẹ̀ títí láé, o jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run;
Enoothong, Kristo ibah rangdah loong raangtaan ih khojoop jaasiit hoonta, erah saarookwe raangtaan ih angla, eno heh ah Rangte dakchah ko adi tongla.
13 láti ìgbà náà, ó retí títí a o fi àwọn ọ̀tá rẹ̀ ṣe àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀.
Eradi Rangte ih heh raawah loong ah heh lanak theng maang thinthin eh banha.
14 Nítorí nípa ẹbọ kan a ti mú àwọn tí a sọ di mímọ́ pé títí láé.
Jaasiit khojoop ih ngo rangdah sa haatta erah loong ah saarookwe raangtaan ih epunthoon ih hoon thuk rumta.
15 Ẹ̀mí Mímọ́ sì ń jẹ́rìí fún wa pẹ̀lú, nítorí lẹ́yìn tí ó wí pé,
Esa Chiiala ih uh seng suh haaki koh tahe. Jaakhoh adi heh ih liita,
16 “Èyí ni májẹ̀mú ti èmi o ba wọn dá lẹ́hìn àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ni Olúwa wí. Èmi o fi òfin mi sí wọn ní ọkàn, inú wọn pẹ̀lú ni èmi o sì kọ wọn sí.”
“Saakaan thok ha doh arah nuumiijeng ah neng damdoh hoon ang Ngah ih nga hootthe rah neng ten nah nopsak ang eno neng khotih nah nep raang ang.” Teesu ih liita.
17 Ó tún sọ wí pé: “Ẹ̀ṣẹ̀ wọn àti àìṣedéédéé wọn lèmi kì yóò sì rántí mọ́.”
Eno heh ih amah we liita, “Ngah ih neng rangdah loong nyia neng thet re loong ah takah dokthun kang.”
18 Ṣùgbọ́n níbi tí ìmúkúrò ìwọ̀nyí bá gbé wà, ìrúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ kò sí mọ́.
Erah thoi biin anaan hoonta dowa ih, rangdah dok haat suh khojoop takah jamka.
19 Ará, ǹjẹ́ bí a ti ní ìgboyà láti wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ nípasẹ̀ ẹ̀jẹ̀ Jesu,
Phoh ano loong, erah raangtaan ih Jisu tek jun ih lacho laphaan Esa Thoon Rum adoh jen wang ih.
20 nípa ọ̀nà títún àti ààyè, tí o yà sí mímọ́ fún wa, àti láti kọjá aṣọ ìkélé èyí yìí ní, ara rẹ̀;
Nyukho ah jun ih seng loong suh lam ena nyia ething lamlaang koh hali—erah langla, Heh teewah sak jun ih.
21 àti bí a ti ni àlùfáà gíga lórí ilé Ọlọ́run;
Seng loong raang ih Rangte nok sokboite elongthoon romwah esiit je ah.
22 ẹ jẹ́ kí a fi òtítọ́ ọkàn súnmọ́ tòsí ni ẹ̀kún ìgbàgbọ́, kí a sì wẹ ọkàn wa mọ́ kúrò nínú ẹ̀rí ọkàn búburú, kí a sì fi omi mímọ́ wẹ ara wa nù.
Erah raang ih Rangte reenah esa tenthun nyia amiimi tuungmaang ah kap ino wang ih, erah damdi seng tenthun ethih dowa saahaat nyia seng sak ah erah joong ih chot choi wang ih.
23 Ẹ jẹ́ kí a di ìjẹ́wọ́ ìrètí wa mu ṣinṣin ni àìṣiyèméjì, nítorí pé olóòtítọ́ ní ẹni tí o ṣe ìlérí.
Marah ten ih jamhi erah laalom ah rongrong eh thin ih, timnge liidih Rangte suh laalom idoh ba heh kakham ah seng jinnah jen thin ih.
24 Ẹ jẹ́ kí a yẹ ara wa wò láti ru ara wa sí ìfẹ́ àti sí iṣẹ́ rere,
Seng laktung nah esok boi mui etheng, huinong ah nong hui mui suh nyia ese reeraang moot suh ah, eno minchan ah noisok mui ih.
25 kí a ma máa kọ ìpéjọpọ̀ ara wa sílẹ̀, gẹ́gẹ́ bi àṣà àwọn ẹlòmíràn; ṣùgbọ́n kí a máa gba ara ẹni níyànjú pẹ̀lúpẹ̀lú bí ẹ̀yin ti rí i pé ọjọ́ náà ń súnmọ́ etílé.
Wahoh ih thinhaat ha likhiik seng laktung nah rangsoom rangtu theng nah chomui tah toihaat ke. Erah nang ibah seng laktung nah ehanhan thong huk baattaan mui ih, sen ih uh ejat ehan Teesu raak Saakaan ah rapne haniik angla.
26 Nítorí bí àwa ba mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ lẹ́yìn ìgbà tí àwa bá ti gba ìmọ̀ òtítọ́ kò tún sí ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ mọ́.
Seng suh amiisak tiit ah jatthuk hali lidoh, jatchoi doh rangdah motkaat karuh mok eh ibah erah rangdah sa haat suh khojoop siik hoon theng takah jeeka.
27 Bí kò ṣe ìrètí ìdájọ́ tí ó ba ni lẹ́rù, àti ti ìbínú ti o múná, tí yóò pa àwọn ọ̀tá run.
Erah naang ibah, Rangte tiit daante thet haat suh dande rangwuung nyia weeluung thok hala ra echo damdoh ban soktheng ba je ah!
28 Ẹnikẹ́ni tí ó ba gan òfin Mose, ó kú láìsí àánú nípa ẹ̀rí ẹni méjì tàbí mẹ́ta.
Ngo ih Moses Hootthe lah chaatka, erah loong ah edande saadoh neng thet re ah dong baat rum ano, wanyi nang ih ehan haakiite mok dong abah, lah minchan thang ih tek haat kah ih rum ah.
29 Mélòó mélòó ni ẹ rò pé a o jẹ ẹni náà ní ìyà kíkan, ẹni tí o tẹ Ọmọ Ọlọ́run mọ́lẹ̀ tí ó sì ti ka ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú ti a fi sọ ọ́ di mímọ́ si ohun àìmọ́, tí ó sì ti kẹ́gàn ẹ̀mí oore-ọ̀fẹ́.
Emah ang abah, ngo ih Rangte Sah ah thetsok haate ah mamah angte ah? eno marah mina ih Rangte nuumiijeng sih ih saasiit rumha asuh thaangniin ngeh thun rumha loong asuh uh mamah angte ang ah? eno Chiiala minchan ah thaangjuute loong asuh uh mamah angte ah? Taatthun thaak an eho chamthuk theng bansok rumha rah timthan echo theng ah!
30 Nítorí àwa mọ ẹni tí o wí pé, Ẹ̀san ni ti èmi, Olúwa wí pé, “Èmi ó gbẹ̀san.” Àti pẹ̀lú, “Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀.”
Timnge liidih erah ngo jengta erah seng ih jat ehi, “Jaadaak ah ngah ih hoon ang, ngah ih ngaak kot ih ang”; eno amah uh eli eta, “Rangte ih heh mina loong ah dande eh ah.”
31 Ohun ẹ̀rù ni láti ṣubú sí ọwọ́ Ọlọ́run alààyè.
Ething Rangte lak khonah dat abah timthan echo etheng ah!
32 Ṣùgbọ́n ẹ rántí ọjọ́ ìṣáájú nínú èyí tí, nígbà tí a ti sí yin lójú, ẹ fi ara da wàhálà ńlá ti ìjìyà;
Dokthun uh an damdi jaakhoh ni mamah angta, Rangte weephaak ah an sak ni ra taha lini ah, an jirep lam ni chamtu, ang abah uh echam enaang rah ih tajen taho.
33 lápákan, nígbà tí a sọ yín di ìran wíwò nípa ẹ̀gàn àti ìpọ́njú; àti lápákan, nígbà tí ẹ̀yin di ẹgbẹ́ àwọn tí a ṣe bẹ́ẹ̀ si.
Tim saasa di an midung ni thaangju rum taho eno rakri rum thuk taho, tim saasa di an thaangju rum taho loong damdi joon tong suh ban tongtu.
34 Nítorí ẹ̀yin bá àwọn tí ó wà nínú ìdè kẹ́dùn, ẹ sì fi ayọ̀ gba ìkólọ ẹrù yin, nítorí ẹ̀yin mọ nínú ara yin pé, ẹ ni ọrọ̀ tí ó wà títí, tí ó sì dára jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Phaatak ni tongte loong damdi roong chamtu, an hupkhaak thaaja rumta di uh an ih tenroon lam ih enaan etu, mamah liidih an ih ejat etu marah thet haat rumta thaknang ibah an ese ngaak chote angtu rah ah, erah hupkhaak ah roitang raangtaan ih ang ah.
35 Nítorí náà ẹ má ṣe gbé ìgboyà yín sọnù, èyí ti o ni èrè ńlá.
An thung nak joong uh mamah liidih erah dowa an ih hethaang ah elong choh uh.
36 Nítorí ẹ̀yin kò le ṣe aláìní sùúrù, nítorí ìgbà tí ẹ̀yin bá ti ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run tan kí ẹ̀yin le gba ìlérí náà.
Rangte thung jun ih re suh nyia Rangte kakham ah chosuh li ubah an ih ejen naan etheng ang ah.
37 Nítorí, “Ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ sí i, ẹni náà ti ń bọ̀ yóò dé, kí yóò sì jáfara.
Mamah liidih rangteele ni baat ha, “Chomroi lidoh, marah eraak ete angla erah wah rah eraak eha; heh tah beenba ka.
38 Ṣùgbọ́n, “Olódodo ni yóò yè nípa ìgbàgbọ́. Ṣùgbọ́n bí o ba fàsẹ́yìn, ọkàn mi kò ní inú dídùn sí i.”
Mamah ang abah uh nga kateng mina loong ih hanpi rum ano ething eh tong rum ah; Enoothong marah mina heh liko ngaak ah, erah mina asuh ngah tah roonkang.”
39 Ṣùgbọ́n àwa kò sí nínú àwọn tí ń fàsẹ́yìn sínú ègbé; bí kò ṣe nínú àwọn tí o gbàgbọ́ sí ìgbàlà ọkàn.
Seng loong heh liko ngaakte nyia emat ete mina likhiik tah angke. Erah nang ibah seng jiinni laalom eje eno seng loong ah epuipang choi.

< Hebrews 10 >