< Hebrews 10 >

1 Nítorí tí òfin jẹ́ òjìji àwọn ohun rere ti ń bọ̀ tí kì í ṣe àwòrán tòótọ́ fún àwọn òtítọ́ náà, wọn kò lè fi ẹbọ kan náà tí wọn ń rú nígbà gbogbo lọ́dọọdún mu àwọn tí ń wá jọ́sìn di pípé.
Kulwokubha ebhilagilo ni lengesi lye misango jekisi jinu ejija, gatali ganu galyabhwelu. Ebhilagilo nakatyali bhitakutula kubhakumisha bhanu abhamufogelela Nyamuanga ku lwainjila ye chogo chinu bhasoshaga abhagabhisi omwaka no mwaka.
2 Bí kò ṣe bẹ́ẹ̀, a kì ìbá tí dẹ́kun àti máa rú wọn, nítorí àwọn ti ń sìn ki ìbá tí ní ìmọ̀ ẹ̀ṣẹ̀, nígbà tí a bá ti wẹ̀ wọ́n mọ́ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Angu ebhyogo ebhyo bhitakeile mbisigwa okusosibhwa? Kwainsonga eyo bhanu abhalamya, bhakabha bhosibhwa lugendo lumwi, bhatakabhee na bhiganilisha bhundi bhwe ebhibhibhi.
3 Ṣùgbọ́n nínú ẹbọ wọ̀nyí ni a ń ṣe ìrántí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́dọọdún.
Nawe mubhyogo omwo kulimo okwijuka ebhibhibhi bhinu bhyakolwaga omwaka no mwaka.
4 Nítorí ko ṣe é ṣe fún ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù àti ti ewúrẹ́ láti mú ẹ̀ṣẹ̀ kúrò.
Kulwokubha itakutulikana kwo lwamba lwa jindume na jimbusi okusoshao ebhibhibhi.
5 Nítorí náà nígbà tí Kristi wá sí ayé, ó wí pé, “Ìwọ kò fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ, ṣùgbọ́n ara ni ìwọ ti pèsè fún mi,
Omwanya gunu Kristo ejile muchalo, aikile ati, “Mutendele bhiyanwa na bhyogo, nawe, mwelabhile omubhili kwa insonga yani.
6 ẹbọ sísun àti ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ ni ìwọ kò ní inú dídùn sí.
Mutabhee na chibhalo mubhiyanwa bhyona gokusimagisibhwa ne bhyogo ingulu ye bhibhibhi.
7 Nígbà náà ni mo wí pé, ‘Kíyèsi i (nínú ìwé kíká ni a gbé kọ ọ́ nípa ti èmi) mo dé láti ṣe ìfẹ́ rẹ, Ọlọ́run.’”
Neile ninaikati, “Lola anu enikola elyenda lyao, Nyamuanga, lwakutyo nandikiwe ingulu yani mubhitabho”.
8 Nígbà tí o wí ni ìṣáájú pé, “Ìwọ kò fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ àti ẹbọ sísun, àti ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò ni inú dídùn si wọn” (àwọn èyí tí a ń rú gẹ́gẹ́ bí òfin).
Aikile lwakutyo jaikilwwe ingulu awo ati: “Mutendele bhyogo, bhiyanwa, nolo bhiyanwa bhyo kusimagisibwa ingulu ye bhibhibhi, na mutakondelewe munda yago” ebhyogo bhinu ebhisosibhwa okulubhana ne bhilagilo.
9 Nígbà náà ni ó wí pé, “Kíyèsi i, mo de láti ṣe ìfẹ́ rẹ Ọlọ́run.” Ó mú ti ìṣáájú kúrò, kí a lè fi ìdí èkejì múlẹ̀.
Neya naikati, “lola, nilyanu okola elyenda lyao”. Natalie kulubhaju obhwitondi bhwo kwamba koleleki akumishe obhwakabhili.
10 Nípa ìfẹ́ náà ni a ti sọ wá di mímọ́ nípa ẹbọ ti Jesu Kristi fi ara rẹ̀ rú lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Kubhwitondi bhwa kabhili, chamalile kwaulwa ku Nyamuanga kulyenda lyae okulabhila okwisosha kwo mubhili gwa Yesu Kristo lugendo lumwi kwo mwanya gwona.
11 Àti olúkúlùkù àlùfáà sì ń dúró lójoojúmọ́ láti ṣiṣẹ́ ìsìn, ó sì ń ṣe ẹbọ kan náà nígbàkígbà, tí kò lè mú ẹ̀ṣẹ̀ kúrò láé.
Nichimali, omugabhisi kemelegulu kwo kufulubhenda kunsiku na kunsiku, nasoshaga echogo chiliya chiliaya, kubhyona bhyona, nakatyali atakatulile okusoshao ebhibhibhi.
12 Ṣùgbọ́n òun, lẹ́yìn ìgbà tí o ti rú ẹbọ kan fún ẹ̀ṣẹ̀ títí láé, o jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run;
Nawe Kristo ejile akasosha echogo lugendo lumwi kulwe ebhibhibhi kajanende kona, enyanjile mukubhoko kwe bhulyo okwa Nyamuanga,
13 láti ìgbà náà, ó retí títí a o fi àwọn ọ̀tá rẹ̀ ṣe àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀.
nalinndilila okukinga abhasoko bheswe bhatulwe ansi bhakolwe bhitebhe ku lwamagulu gae.
14 Nítorí nípa ẹbọ kan a ti mú àwọn tí a sọ di mímọ́ pé títí láé.
Kulwokubha kwa injila yo kusosibhwa lumwi abhakumisishe kajanende bhanu bhauhywe ku Nyamuanga.
15 Ẹ̀mí Mímọ́ sì ń jẹ́rìí fún wa pẹ̀lú, nítorí lẹ́yìn tí ó wí pé,
Na Mwoyo Mwelu ona kachibhambalila kwiswe. Kulwokubha aikile okwamba ati,
16 “Èyí ni májẹ̀mú ti èmi o ba wọn dá lẹ́hìn àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ni Olúwa wí. Èmi o fi òfin mi sí wọn ní ọkàn, inú wọn pẹ̀lú ni èmi o sì kọ wọn sí.”
“Linu nilagano linu nilikola amwi nabho jikalabha jinsiku ejo; kaika Latabhugenyi: enitamo ebhilagilo bhyani mumioyo jebhwe, na nilijandika mubhwenge bhwebhwe”.
17 Ó tún sọ wí pé: “Ẹ̀ṣẹ̀ wọn àti àìṣedéédéé wọn lèmi kì yóò sì rántí mọ́.”
Niwo neya naikati, “Bhatalijuka lindi ebhibhibhi bhyebhwe nebhikolwa bhyebhwe ebhifuye”.
18 Ṣùgbọ́n níbi tí ìmúkúrò ìwọ̀nyí bá gbé wà, ìrúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ kò sí mọ́.
Woli olubhaju lunu luli no kwiswalililwa kubhanu, gutalio lindi echogo chona chona kulwe ebhibhibhi.
19 Ará, ǹjẹ́ bí a ti ní ìgboyà láti wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ nípasẹ̀ ẹ̀jẹ̀ Jesu,
Kulwejo, bhana bhasu, chitana ebhasi lyo kwingila olubhaju olwelu muno kwa manyinga ga Yesu.
20 nípa ọ̀nà títún àti ààyè, tí o yà sí mímọ́ fún wa, àti láti kọjá aṣọ ìkélé èyí yìí ní, ara rẹ̀;
Inu ninjila inu aiguye ingulu yeswe kwa injila yo mubhili b gwae, muyaya nagunu gulamile okulabhila mwi pajiya.
21 àti bí a ti ni àlùfáà gíga lórí ilé Ọlọ́run;
Na kwainsonga eyo chinage omugabhisi mukulu munyumba ya Nyamuanga,
22 ẹ jẹ́ kí a fi òtítọ́ ọkàn súnmọ́ tòsí ni ẹ̀kún ìgbàgbọ́, kí a sì wẹ ọkàn wa mọ́ kúrò nínú ẹ̀rí ọkàn búburú, kí a sì fi omi mímọ́ wẹ ara wa nù.
na chimufogelele kwo mwoyo gwe chimali mubhulengelesi bhwechimali mulikilisha chili ne mioyo jinu jilijakisi okusoka mubhujabhi mumitima ne mibhili jeswe jinu josibhwe kwa manji ganu gali gakisi.
23 Ẹ jẹ́ kí a di ìjẹ́wọ́ ìrètí wa mu ṣinṣin ni àìṣiyèméjì, nítorí pé olóòtítọ́ ní ẹni tí o ṣe ìlérí.
Mbe chigwatilile kwo kwigumisilisha mukuta kwa libhasi kwo kwiikanya kweswe, obhutainduka, kulwokubha Nyamuanga unu alagile ni mwiikanyibhwa.
24 Ẹ jẹ́ kí a yẹ ara wa wò láti ru ara wa sí ìfẹ́ àti sí iṣẹ́ rere,
Na chibhe bhokwiganilisha abhenela chikomeshanyega bhuli umwi ende ebhikolwa bhyo bhwana.
25 kí a ma máa kọ ìpéjọpọ̀ ara wa sílẹ̀, gẹ́gẹ́ bi àṣà àwọn ẹlòmíràn; ṣùgbọ́n kí a máa gba ara ẹni níyànjú pẹ̀lúpẹ̀lú bí ẹ̀yin ti rí i pé ọjọ́ náà ń súnmọ́ etílé.
Na chitasigaga okwikumanya amwi, lwakutyo abhakola abhandi. Nchikomeshana bhuli umwi lindi na lindi, lwakutyo omulola olusiku lweiliye.
26 Nítorí bí àwa ba mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ lẹ́yìn ìgbà tí àwa bá ti gba ìmọ̀ òtítọ́ kò tún sí ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ mọ́.
Labha chikakolela chigundu okugendelela okukola ebhibhibhi chamalile okulamila obhwengeso bhwe chimali, Echogo echindi che bhibhibhi itakusigalao lindi.
27 Bí kò ṣe ìrètí ìdájọ́ tí ó ba ni lẹ́rù, àti ti ìbínú ti o múná, tí yóò pa àwọn ọ̀tá run.
Ikamala, yasigaewo okulindilila indamu yo kubhaisha, no bhululu bhwo mulilo gunu gulibhasingalisha abhasoko bha Nyamuanga.
28 Ẹnikẹ́ni tí ó ba gan òfin Mose, ó kú láìsí àánú nípa ẹ̀rí ẹni méjì tàbí mẹ́ta.
Wona wona unu alemele ebhilagilo bhya Musa kafwa atana chigongo imbele yo bhubhambasi bhwabhanu bhabhili nolo bhasatu.
29 Mélòó mélòó ni ẹ rò pé a o jẹ ẹni náà ní ìyà kíkan, ẹni tí o tẹ Ọmọ Ọlọ́run mọ́lẹ̀ tí ó sì ti ka ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú ti a fi sọ ọ́ di mímọ́ si ohun àìmọ́, tí ó sì ti kẹ́gàn ẹ̀mí oore-ọ̀fẹ́.
ndengoki okukila eyo eyalisungu chimwiile bhuli umwi unu agaile omwana wa Nyamuanga, wona wona unu aikolee insagama ya indagano kuti chinu chinu chitali chelu, insagama eyo kwiyo aitee ku Nyamuanga- wona wona unu amufumile Omwoyo we chigongo?
30 Nítorí àwa mọ ẹni tí o wí pé, Ẹ̀san ni ti èmi, Olúwa wí pé, “Èmi ó gbẹ̀san.” Àti pẹ̀lú, “Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀.”
Kulwokubha echimenya oumwi unu aikile ati,”Okusubhya jinsili ni kwani, eniliya”. Nalindi, “Latabhugenyi alibhalamula abhanu bhae”.
31 Ohun ẹ̀rù ni láti ṣubú sí ọwọ́ Ọlọ́run alààyè.
Ni musango gwo kubhaisha omunu okugwila mumabhoko ga Nyamuanga unu alamile!
32 Ṣùgbọ́n ẹ rántí ọjọ́ ìṣáájú nínú èyí tí, nígbà tí a ti sí yin lójú, ẹ fi ara da wàhálà ńlá ti ìjìyà;
Nawe ichuka jinsiku jinu jalabhile, wejile mwatulwako kwimwe obhwelu, nikutiki kutyo mwatulile okwikomesha obhusasi bhamfu.
33 lápákan, nígbà tí a sọ yín di ìran wíwò nípa ẹ̀gàn àti ìpọ́njú; àti lápákan, nígbà tí ẹ̀yin di ẹgbẹ́ àwọn tí a ṣe bẹ́ẹ̀ si.
Mwaliga mutehye abhwelu mukufumwa nokujimibhwa no kunyansibhwa, na aliga muli bhasangisi amwi nabhanu bhabhwene okunyansibhwa kama kutyo.
34 Nítorí ẹ̀yin bá àwọn tí ó wà nínú ìdè kẹ́dùn, ẹ sì fi ayọ̀ gba ìkólọ ẹrù yin, nítorí ẹ̀yin mọ nínú ara yin pé, ẹ ni ọrọ̀ tí ó wà títí, tí ó sì dára jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Kulwokubha aliga muli no mwoyo gwe chigongo kubhanu bhaliga bhabhoelwe, na mwalamiye kwa likondelewe okunyansibhwa kwo mwandu gwemwe, mumenyati emwona abhene mwaliga muli bhali bhwo mwandu gwo kulama kajanende.
35 Nítorí náà ẹ má ṣe gbé ìgboyà yín sọnù, èyí ti o ni èrè ńlá.
Kulwejo musige kwesa libhasi lyemwe, bhunu bhuli nebhiyanwa bhyamfu.
36 Nítorí ẹ̀yin kò le ṣe aláìní sùúrù, nítorí ìgbà tí ẹ̀yin bá ti ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run tan kí ẹ̀yin le gba ìlérí náà.
Kulwokubha omwenda okwigumilisha, koleleki mubhone okulamila chinu Nyamuanga alagile, ejile amala okukola elyenda lyae.
37 Nítorí, “Ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ sí i, ẹni náà ti ń bọ̀ yóò dé, kí yóò sì jáfara.
Kulwokubha guchalio omwanya mutoto, oumwi unu kaja, kaja chimali na atakukola.
38 Ṣùgbọ́n, “Olódodo ni yóò yè nípa ìgbàgbọ́. Ṣùgbọ́n bí o ba fàsẹ́yìn, ọkàn mi kò ní inú dídùn sí i.”
Omulengelesi wani kalama kwe likisha. Labha akasubha inyuma, nitakukondelelwa nage.” Nawe eswe chitali kama lwabhanu abhasubha inyuma kwo kusimagila.
39 Ṣùgbọ́n àwa kò sí nínú àwọn tí ń fàsẹ́yìn sínú ègbé; bí kò ṣe nínú àwọn tí o gbàgbọ́ sí ìgbàlà ọkàn.
Nawe eswe, chili amwi ya bhaliya bhanu chili ne likilisha no kujilinda emitima jeswe

< Hebrews 10 >