< Haggai 2 >

1 Ní ọjọ́ kọkànlélógún oṣù keje, ni ọ̀rọ̀ Olúwa wá nípasẹ̀ wòlíì Hagai wí pé,
Detta skedde på tjugufjärde dagen i sjätte månaden av konung Darejaves' andra regeringsår.
2 “Sọ fún Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, baálẹ̀ Juda, àti Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà àti àwọn ènìyàn yòókù. Béèrè lọ́wọ́ wọn pé,
I sjunde månaden, på tjuguförsta dagen i månaden, kom HERRENS ord genom profeten Haggai han sade:
3 ‘Ta ni nínú yín tí ó kù tí ó sì ti rí ilé yìí ní ògo rẹ̀ àkọ́kọ́? Báwo ni ó ṣe ri sí yín nísinsin yìí? Ǹjẹ́ kò dàbí asán lójú yín?
Säg till Serubbabel, Sealtiels son Juda ståthållare, och till översteprästen Josua, Josadaks son, och till kvarlevan av folket:
4 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, múra gírí, ìwọ Serubbabeli,’ ni Olúwa wí. ‘Múra gírí, ìwọ Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà. Ẹ sì múra gírí gbogbo ẹ̀yin ènìyàn ilẹ̀ náà,’ ni Olúwa wí, ‘kí ẹ sì ṣiṣẹ́. Nítorí èmi wà pẹ̀lú yín,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Leva icke ännu bland eder män kvar, som hava sett detta hus i dess forna härlighet? Och hurudant sen I det nu vara? Är det icke såsom intet i edra ögon?
5 ‘Èyí ni ohun tí Èmi fi bá a yín dá májẹ̀mú nígbà tí ẹ jáde kúrò ní Ejibiti, bẹ́ẹ̀ ni Ẹ̀mí ì mi sì wà pẹ̀lú yín. Ẹ má ṣe bẹ̀rù.’
Men var likväl nu frimodig, du Serubbabel, säger HERREN; och var frimodig, du överstepräst Josua, Josadaks son; och varen frimodiga och arbeten, alla I som hören till folket i landet, säger HERREN; ty jag är med eder, säger HERREN Sebaot.
6 “Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Láìpẹ́ jọjọ, Èmi yóò mi àwọn ọrun àti ayé, Òkun àti ìyàngbẹ ilẹ̀ lẹ́ẹ̀kan sí i.
Det förbund som jag slöt med eder, när I drogen ut ur Egypten, vill jag låta stå fast, och min Ande skall förbliva ibland eder; frukten icke.
7 Èmi yóò mi gbogbo orílẹ̀-èdè, ìfẹ́ gbogbo orílẹ̀-èdè yóò fà sí tẹmpili yìí, Èmi yóò sì kún ilé yìí pẹ̀lú ògo,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Ty så säger HERREN Sebaot: Ännu en gång, inom en liten tid, skall jag komma himmelen och jorden, havet och det torra att bäva;
8 ‘Tèmi ni fàdákà àti wúrà,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
och alla hednafolk skall jag komma att bäva, och så skola dyrbara håvor från alla hednafolk föras hit; och jag skall fylla detta hus med härlighet, säger HERREN Sebaot.
9 ‘Ògo ìkẹyìn ilé yìí yóò pọ̀ ju ti ìṣáájú lọ,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, ‘Àti ní ìhín yìí ni Èmi ó sì fi àlàáfíà fún ni,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”
Ty mitt är silvret, och mitt är guldet, säger HERREN Sebaot.
10 Ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹsànán ní ọdún kejì Dariusi, ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ wòlíì Hagai wá pé,
Den tillkommande härligheten hos detta hus skall bliva större än dess forna var, säger HERREN Sebaot; och på denna plats skall jag låta friden råda, säger HERREN Sebaot.
11 “Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, ‘Béèrè lọ́wọ́ àwọn àlùfáà ohun tí òfin wí pé:
På tjugufjärde dagen i nionde månaden av Darejaves' andra regeringsår kom HERRENS ord till profeten Haggai; han sade:
12 Bí ẹnìkan bá gbé ẹran mímọ́ ní ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀, tí ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀ kan àkàrà tàbí ọbẹ̀, wáìnì, òróró tàbí oúnjẹ mìíràn, ǹjẹ́ yóò ha jẹ́ mímọ́ bí?’” Àwọn àlùfáà sì dáhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́.”
Så säger HERREN Sebaot: Fråga prästerna om lag och säg:
13 Nígbà náà ni Hagai wí pé, “Bí ẹnìkan tí ó jẹ́ aláìmọ́ nípa fífi ara kan òkú bá fi ara kan ọ̀kan lára nǹkan wọ̀nyí, ǹjẹ́ yóò ha jẹ́ aláìmọ́?” Àwọn àlùfáà sì dáhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, yóò jẹ́ aláìmọ́.”
»Om någon bär heligt kött i fliken av sin mantel och så med fliken kommer vid något bakat eller kokt, eller vid vin eller olja, eller vid något annat som man förtär, månne detta därigenom bliver heligt?» Prästerna svarade och sade: »Nej.»
14 Nígbà náà ni Hagai dáhùn ó sì wí pé, “‘Bẹ́ẹ̀ ni ènìyàn wọ̀nyí rí, bẹ́ẹ̀ sì ni orílẹ̀-èdè yìí rí níwájú mi,’ ni Olúwa wí. ‘Bẹ́ẹ̀ sì ni olúkúlùkù iṣẹ́ ọwọ́ wọn; èyí tí wọ́n sì fi rú ẹbọ níbẹ̀ jẹ́ aláìmọ́.
Åter frågade Haggai: »Om den som har blivit orenad genom en död kommer vid något av allt detta, månne det då bliver orenat?» Prästerna svarade och sade: »Ja.»
15 “‘Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ ro èyí dáradára láti òní yìí lọ, ẹ kíyèsi bí nǹkan ṣe rí tẹ́lẹ̀, a to òkúta kan lé orí èkejì ní tẹmpili Olúwa.
Då tog Haggai till orda och sade: »Så är det med detta folk och så är det med detta släkte inför mig, säger HERREN, och så är det med allt deras händers verk: vad de där offra, det är orent.
16 Nígbà tí ẹnikẹ́ni bá dé ibi òkìtì òsùwọ̀n ogun, mẹ́wàá péré ni yóò ba níbẹ̀. Nígbà tí ẹnikẹ́ni bá dé ibi ìfúntí wáìnì láti wọn àádọ́ta ìwọ̀n, ogún péré ni yóò ba níbẹ̀.
Och given nu akt på huru det hittills har varit, före denna dag, och under tiden innan man ännu hade begynt lägga sten på sten till HERRENS tempel
17 Mo fi ìrẹ̀dànù, ìmúwòdù àti yìnyín bá gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín jẹ; síbẹ̀ ẹ̀yin kò yípadà sí ọ̀dọ̀ mi,’ ni Olúwa wí.
huru härförinnan, om någon kom till en sädesskyl som skulle giva tjugu mått, den gav allenast tio, och huru, om någon kom till vinpressen för att ösa upp femtio kärl, den gav allenast tjugu.
18 ‘Láti òní lọ, láti ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹsànán yìí kí ẹ kíyèsi, kí ẹ sì rò ó dáradára, ọjọ́ ti a fi ìpìlẹ̀ tẹmpili Olúwa lélẹ̀, rò ó dáradára.
Vid allt edra händers arbete slog jag eder säd med sot och rost och hagel, och likväl vänden I eder icke till mig, säger HERREN.
19 Ǹjẹ́ èso ha wà nínú abà bí? Títí di àkókò yìí, àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ àti pomegiranate, àti igi olifi kò ì tí ì so èso kankan. “‘Láti òní lọ ni èmi yóò bùkún fún un yin.’”
Given alltså akt på huru det hittills har varit, före denna dag; ja, given akt på huru det har varit före tjugufjärde dagen i nionde månaden, denna dag då grunden har blivit lagd till HERRENS tempel.
20 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tún tọ Hagai wá nígbà kejì, ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù náà pé,
Finnes någon säd ännu i kornboden? Nej; och varken vinträdet eller fikonträdet eller granatträdet eller olivträdet har ännu burit någon frukt. Men från denna dag skall jag giva välsignelse.»
21 “Sọ fún Serubbabeli baálẹ̀ Juda pé èmi yóò mi àwọn ọ̀run àti ayé.
Och HERRENS ord kom för andra gången till Haggai, på tjugufjärde dagen i samma månad; han sade:
22 Èmi yóò bi ìtẹ́ àwọn ìjọba ṣubú, Èmi yóò sì pa agbára àwọn aláìkọlà run, Èmi yóò sì dojú àwọn kẹ̀kẹ́ ogun dé, àti àwọn tí ń gùn wọ́n; ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin yóò ṣubú; olúkúlùkù nípa idà arákùnrin rẹ̀.”
Säg till Serubbabel, Juda ståthållare: Jag skall komma himmelen och jorden att bäva;
23 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Ní ọjọ́ náà, ìwọ ìránṣẹ́ mi Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, Èmi yóò mú ọ, Èmi yóò sì sọ ọ di bí òrùka èdìdì mi, nítorí mo ti yan ọ, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”
jag skall omstörta konungatroner och göra hednarikenas makt till intet; jag skall omstörta vagnarna med sina kämpar, och hästarna skola stupa med sina ryttare. Den ene skall falla för den andres svärd. På den tiden, säger HERREN Sebaot, skall jag taga dig, min tjänare Serubbabel, Sealtiels son, säger HERREN, och skall akta dig såsom min signetring; ty dig har jag utvalt, säger HERREN Sebaot.

< Haggai 2 >