< Haggai 1 >

1 Ní ọdún kejì ọba Dariusi ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹfà, ọ̀rọ̀ Olúwa wá nípasẹ̀ wòlíì Hagai sí Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, baálẹ̀ Juda, àti sọ́dọ̀ Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà.
Darius manghai kah a kum nit nah, a hla la hla rhuk, hnin at vaengah, BOEIPA ol te tonghma Haggai kut lamloh, Judah rhalboei Shealtiel capa Zerubbabel ham neh khosoih Jehozadak capa Joshua puei ham pai tih,
2 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Àwọn ènìyàn wọ̀nyí wí pé, ‘Kò tí ì tó àkókò láti kọ́ ilé Olúwa.’”
Caempuei BOEIPA loh he ni a thui. Pilnam he thui pah lah. ‘BOEIPA im sak ham tue he, a tue pai hlan’ a ti uh he,” a ti.
3 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa wá láti ọ̀dọ̀ wòlíì Hagai wí pé,
BOEIPA ol he tonghma Haggai kut lamloh cet bal tih,
4 “Ǹjẹ́ àkókò ni fún ẹ̀yin fúnra yín láti máa gbé ní ilé tí a ṣe ní ọ̀ṣọ́ nígbà tí ilé yìí wà ni ahoro?”
Nangmih te namamih bueng na im khop ah khosak ham tue a? Tedae im he kaksap coeng he.
5 Nísìnsinyìí, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ kíyèsi ọ̀nà yín.
Te dongah caempuei BOEIPA loh he ni a thui coeng. Na longpuei te na thinko ah dueh laeh.
6 Ẹ̀yin ti gbìn ohun ti ó pọ̀. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kórè díẹ̀ níbẹ̀. Ẹ̀yin jẹun, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò yó. Ẹ̀yin mu ṣùgbọ́n kò tẹ́ ẹ yín lọ́run; ẹ̀yin wọ aṣọ, ṣùgbọ́n kò mú òtútù yin lọ; ẹyin gba owó iṣẹ́ ṣùgbọ́n ẹ ń gbà á sínú ajádìí àpò.”
Muep na tuh dae a yol la pawk. A caak dae a cungnah la om pawh. A ok akhaw rhuihmil hae pawh. Bai cakhaw a bae hae moenih. Kutloh loh a kutloh akhaw hnocun put hae.
7 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ kíyèsi ọ̀nà yín.
Caempuei BOEIPA loh he ni a thui. Na longpuei te na thinko ah dueh laeh.
8 Ẹ gun orí àwọn òkè ńlá lọ, kí ẹ sì mú igi wá pẹ̀lú yín. Kí ẹ sì kọ́ ilé náà, kí inú mi bà le è dùn sí i, kí a sì yín mí lógo,” ni Olúwa wí.
“Tlang la luei uh lamtah thing lo uh laeh. Im he sa uh laeh. A khui ah ngaingaih saeh lamtah ka thangpom khaw ka thangpom mai eh,” tila BOEIPA loh a thui.
9 “Ẹyin ti ń retí ọ̀pọ̀, ṣùgbọ́n kíyèsi i, o yípadà sí díẹ̀. Ohun tí ẹ̀yin mú wa ilé, èmi sì fẹ́ ẹ dànù. Nítorí kí ni?” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Nítorí ilé mi tí ó dahoro; tí olúkúlùkù yín sì ń sáré fún ilé ara rẹ̀.
A yet la a mael thil dae a yol la poeh coeng te. Im la na khuen uh vaengah te te phawn ka hmuh. Balae tih caempuei BOEIPA kah olphong a om? Ka im he a kaksap vaengah nangmih kah hlang mai tah, amah im neh cungpoeh uh.
10 Nítorí yín ni àwọn ọ̀run ṣe dá ìrì dúró tí ilẹ̀ sì kọ̀ láti mu èso jáde.
“Te dongah nangmih ham tah vaan loh buemtui a hloh uh vetih, diklai loh a cangpai a hloh ni.
11 Mo sì ti pe ọ̀dá sórí ilẹ̀ àti sórí àwọn òkè ńlá, sórí ọkà àti sórí wáìnì tuntun, sórí òróró àti sórí ohun ti ilẹ̀ ń mú jáde, sórí ènìyàn, sórí ẹran àti sórí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín.”
“Diklai hman neh tlang soah khaw, cangpai so neh misur thai soah khaw, situi so neh diklai kah a thoeng boeih soah khaw, hlang so neh rhamsa soah khaw, kut dongkah thaphu boeih soah khaw kholing ka khue thil ni,” a ti nah.
12 Nígbà náà ni Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà pẹ̀lú gbogbo ènìyàn ìyókù, gba ohùn Olúwa Ọlọ́run wọn gbọ́ àti ọ̀rọ̀ wòlíì Hagai, nítorí Olúwa Ọlọ́run ni ó rán an. Àwọn ènìyàn sì bẹ̀rù Olúwa.
Te dongah Shealtiel capa Zerubbabel neh khosoih puei Jehozadak capa Joshua long khaw, pilnam kah a meet boeih long khaw a Pathen BOEIPA ol neh tonghma Haggai ol te a ngai. Anih te a Pathen BOEIPA loh a tueih coeng dongah pilnam te BOEIPA mikhmuh ah rhih uh.
13 Nígbà náà ni Hagai ìránṣẹ́ Olúwa ń jíṣẹ́ Olúwa fún àwọn ènìyàn pé, “Èmí wà pẹ̀lú yín,” ni Olúwa wí.
Te phoeiah BOEIPA kah puencawn Haggai loh BOEIPA kah olthui te pilnam taengah a thui pah. Te vaengah, “Kai tah nangmih taengah BOEIPA kah olphong ni,” a ti nah.
14 Nítorí náà, Olúwa ru ẹ̀mí Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli sókè, baálẹ̀ Juda àti ẹ̀mí Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà àti ẹ̀mí gbogbo ènìyàn ìyókù. Wọ́n sì wá, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣiṣẹ́ lórí ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run wọn,
Te vaengah BOEIPA loh Judah rhalboei Shealtiel capa Zerubbabel kah mueihla te khaw, khosoih puei Jehozadak capa Joshua kah mueihla khaw, pilnam a meet boeih kah mueihla khaw a haeng pah. Te dongah kun uh tih a Pathen caempuei YAHWEH im ah bitat te,
15 ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹfà ní ọdún kejì ọba Dariusi.
manghai Darius kah kum bae nah, hla rhuk hnin kul hnin li vaengah a saii uh.

< Haggai 1 >