< Habakkuk 2 >

1 Èmi yóò dúró lórí ibusọ́ mi láti máa wòye, èmi yóò sì gbé ara mi ka orí alóre, èmi yóò si ṣọ́ láti gbọ́ ohun tí yóò sọ fún mi àti èsì ti èmi yóò fún ẹ̀sùn yìí nígbà tó bá ń bá mi wí.
Na straży swej stać będę, i stanę na baszcie, wyglądając, abym obaczył, co będzie Bóg mówił, cobym miał odpowiedzieć po karaniu mojem.
2 Nígbà náà ni Olúwa dáhùn pé, “Kọ ìṣípayá náà sílẹ̀ kí o sì fi hàn ketekete lórí wàláà kí ẹni tí ń kà á, lè máa sáré.
Tedy mi odpowiedział Pan, mówiąc: Napisz widzenie, a napisz rzetelnie na tablicach, aby je prędko czytelnik przeczytał,
3 Nítorí ìṣípayá náà jẹ́ tí ìgbà kan tí a múra sílẹ̀ dè; yóò máa yára sí ìgbẹ̀yìn kí yóò sìsọ èké. Bí o tilẹ̀ lọ́ra, dúró dè é; nítorí, dájúdájú, yóò dé, kí yóò sí pẹ́.”
Przeto, że jeszcze do pewnego czasu odłożone jest widzenie, które wypowie na skończeniu jego, a nie skłamie; a jeźliby na chwilę odwłaczał, oczekuj nań; boć zapewne przyjdzie, a nie omieszka.
4 “Kíyèsi, ọkàn rẹ tí ó gbéga, ìfẹ́ rẹ̀ kò dúró ṣinṣin nínú rẹ̀, ṣùgbọ́n olódodo yóò wa nípa ìgbàgbọ́ rẹ̀.
Oto kto sobie hardzie poczyna, tego dusza nie jest szczera w nim; ale sprawiedliwy z wiary swej żyć będzie.
5 Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lú, nítorí tí ọtí wáìnì ni ẹ̀tàn, agbéraga ènìyàn òun, kò sì ní sinmi ẹni tí ó sọ ìwọra rẹ di gbígbòòrò bí isà òkú, ó sì dàbí ikú, a kò sì le tẹ́ ẹ lọ́rùn, ó kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ sí ọ̀dọ̀ ó sì gba gbogbo ènìyàn jọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. (Sheol h7585)
Dopieroż człowiek opiły, przewrotny i hardy nie ostoi się w mieszkaniu swojem, który rozszerza jako piekło duszę swoję, a jest jako śmierć, która się nie może nasycić, choćby zgromadził do siebie wszystkie narody, a zebrał do siebie wszystkich lud zi. (Sheol h7585)
6 “Gbogbo àwọn wọ̀nyí kì yóò máa pa òwe sí i tí wọn yóò sì máa kọ orin òwe sí i wí pé, “‘Ègbé ni fún ẹni tí ń mu ohun tí kì í ṣe tirẹ̀ pọ̀ sí i! Tí ó sì sọ ara rẹ̀ di ọlọ́rọ̀ nípasẹ̀ ìlọ́nilọ́wọ́gbà! Eléyìí yóò ha ti pẹ́ tó?’
Izali ci wszyscy o nim przypowieści nie uczynią i wykładów i gadanin o nim? mówiąc: Biada temu, który rozmnaża rzeczy nie swoje, ( a dokądże? ) i obciąża się gęstem błotem!
7 Ǹjẹ́ ẹni ti ó yọ ọ́ lẹ́nu, kí yóò ha dìde ní òjijì? Àti àwọn tí ó wàhálà rẹ kì yóò jí, kí wọn ó sì dẹ́rùbà ọ́? Nígbà náà ni ìwọ yóò wa dí ìkógun fún wọn.
Izali nie powstaną z prędka, którzy cię kąsać będą, i nie ocucą się, którzy cię szarpać będą? i staniesz się im łupem.
8 Nítorí ìwọ ti kó Orílẹ̀-èdè púpọ̀, àwọn ènìyàn tókù yóò sì kó ọ nítorí ìwọ tí ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀; nítorí ẹ̀jẹ̀, ìwọ tí pa ilẹ̀ àti ìlú ńlá run àti gbogbo ènìyàn to ń gbé inú rẹ̀.
Bo iżeś ty złupił wiele narodów, złupią cię też wszystkie ostatki narodów, dla krwi ludzkiej i dla gwałtu uczynionego ziemi i miastu i wszystkim, którzy mieszkają w niem.
9 “Ègbé ni fún ẹni tí ń jẹ èrè ìjẹkújẹ sí ilé rẹ̀, tí o sí gbé ìtẹ́ rẹ̀ lórí ibi gíga, kí a ba le gbà á sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ibi!
Biada temu, który łakomie szuka zysku szkaradnego domowi swemu, aby wystawił wysoko gniazdo swoje, a tak uszedł z mocy złego!
10 Ìwọ ti gbìmọ̀ ìtìjú sí ilé rẹ nípa kíké ènìyàn púpọ̀ kúrò; ìwọ sì ti pàdánù ẹ̀mí rẹ.
Uradziłeś hańbę domowi swemu, abyś wytracił wiele narodów, a grzeszył przeciwko duszy swojej.
11 Nítorí tí òkúta yóò kígbe jáde láti inú ògiri wá, àti ìtí igi láti inú igi rírẹ́ wá yóò sì dá a lóhùn.
Albowiem kamień z muru wołać będzie, i sęk z drzewa wyda o tem świadectwo.
12 “Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ẹ̀jẹ̀ kọ́ ìlú, tí o sì fi àìṣedéédéé tẹ ìlú ńlá dó?
Biada temu, który krwią buduje miasto, a utwierdza miasta nieprawością!
13 Olúwa àwọn ọmọ-ogun kò ha ti ṣètò rẹ̀ pé làálàá àwọn ènìyàn jẹ́ epo fún iná kí àwọn orílẹ̀-èdè náà sì máa ṣe wàhálà fún asán?
Azaż to nie jest od Pana zastępów, iż koło czego ludzie pracują, to ogień skazi, a nad czem się narody spracowały, to nadaremno będzie?
14 Nítorí tí ayé yóò kún fún ìmọ̀ ògo Olúwa, bí omi ti bo Òkun.
Albowiem ziemia będzie napełniona znajomością chwały Pańskiej, jako morze wody napełniają.
15 “Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ohun mímu fún aládùúgbò rẹ̀, tí ó sì fi ọtí-lílé rẹ̀ fún un, tí o sì jẹ́ kó mu àmupara, kí ìwọ kí ó ba lè wo ìhòhò wọn.”
Biada temu, który poi bliźniego swego, przystawiając naczynia swego, tak aby go upoił, i napatrzył się nagości jego!
16 Ìtìjú yóò bò ọ́ dípò ògo, ìwọ náà mu pẹ̀lú kí ìhòhò rẹ kí ó lè hàn, ago ọwọ́ ọ̀tún Olúwa, yóò yípadà sí ọ, ìtìjú yóò sì bo ògo rẹ.
Nasycisz się hańby dla sławy; pić będziesz i ty, a obnażony będziesz; obróci się do ciebie kielich prawicy Pańskiej, i zwrócenie sromotne przyjdzie na sławę twoję.
17 Nítorí ìwà ipá tí ó tí hù sí Lebanoni yóò bò ọ́, àti ìparun àwọn ẹranko yóò dẹ́rùbà ọ́ mọ́lẹ̀. Nítorí ìwọ tí ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀; ìwọ tí pa ilẹ̀ náà àti ìlú ńlá run àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
Bo cię łupiestwo Libanu okryje i spustoszenie zwierząt, które ich straszyło: dla krwi ludzkiej i dla gwałtu ziemi i miasta, i wszystkich, którzy mieszkają w niem.
18 “Èrè kí ni òrìṣà ni, tí oníṣọ̀nà rẹ̀ fi gbẹ́ ẹ, ère dídá ti ń kọ ni èké? Nítorí ti ẹni ti ó dá a gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé ohun tí ó fúnra rẹ̀ dá; ó sì mọ ère tí kò le fọhùn.
Cóż pomoże ryty obraz, że go wyrył rzemieślnik jego? albo odlewany obraz i nauczyciel kłamstwa, że ufa rzemieślnik w robocie swojej, czyniąc bałwany nieme?
19 Ègbé ni fún ẹni ti ń sọ fún igi pé, ‘Di alààyè?’ Fún òkúta tí kò lè fọhùn pé, ‘Dìde.’ Ǹjẹ́ òun lè tọ́ ni sí ọ̀nà? Wúrà àti fàdákà ni a fi bò ó yíká; kò sì sí èémí kan nínú rẹ.”
Biada temu! który mówi drewnu: Ocuć się, a kamieniowi niememu: Obudź się! Tenże to ma uczyć? Spojrzyj nań, powleczonyć jest złotem i srebrem; ale w nim niemasz zgoła żadnego ducha.
20 Ṣùgbọ́n Olúwa wà nínú tẹmpili mímọ́ rẹ̀; ẹ jẹ́ kí gbogbo ayé parọ́rọ́ níwájú rẹ.
Pan jest w kościele świętobliwości swojej; umilknij przed obliczem jego wszystka ziemio!

< Habakkuk 2 >