< Habakkuk 2 >
1 Èmi yóò dúró lórí ibusọ́ mi láti máa wòye, èmi yóò sì gbé ara mi ka orí alóre, èmi yóò si ṣọ́ láti gbọ́ ohun tí yóò sọ fún mi àti èsì ti èmi yóò fún ẹ̀sùn yìí nígbà tó bá ń bá mi wí.
Jeg vil staa paa min Vagt og stille mig paa Varen og spejde for at se, hvad han vil tale til mig, og hvad jeg skal svare paa min Klage.
2 Nígbà náà ni Olúwa dáhùn pé, “Kọ ìṣípayá náà sílẹ̀ kí o sì fi hàn ketekete lórí wàláà kí ẹni tí ń kà á, lè máa sáré.
Og Herren svarede mig og sagde: Skriv Synet, og gør det tydeligt paa Tavlerne, for at den, som læser det, kan gøre det i en Fart.
3 Nítorí ìṣípayá náà jẹ́ tí ìgbà kan tí a múra sílẹ̀ dè; yóò máa yára sí ìgbẹ̀yìn kí yóò sìsọ èké. Bí o tilẹ̀ lọ́ra, dúró dè é; nítorí, dájúdájú, yóò dé, kí yóò sí pẹ́.”
Thi endnu gaar Synet paa den bestemte Tid, og det taler om Enden og lyver ikke; dersom det tøver, da bi efter det; thi det skal visselig komme, det skal ikke udeblive.
4 “Kíyèsi, ọkàn rẹ tí ó gbéga, ìfẹ́ rẹ̀ kò dúró ṣinṣin nínú rẹ̀, ṣùgbọ́n olódodo yóò wa nípa ìgbàgbọ́ rẹ̀.
Se, opblæst og ikke ydmyg er hans Sjæl i ham; men den retfærdige skal leve ved sin Tro.
5 Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lú, nítorí tí ọtí wáìnì ni ẹ̀tàn, agbéraga ènìyàn òun, kò sì ní sinmi ẹni tí ó sọ ìwọra rẹ di gbígbòòrò bí isà òkú, ó sì dàbí ikú, a kò sì le tẹ́ ẹ lọ́rùn, ó kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ sí ọ̀dọ̀ ó sì gba gbogbo ènìyàn jọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. (Sheol )
Saa er og Vinen en Bedrager; en hovmodig Mand skal ikke bestaa, han, der som Dødsriget opspiler sit Svælg og er som Døden, saa han ikke mættes; og han sankede til sig alle Folkeslag og samlede til sig alle Folkestammer. (Sheol )
6 “Gbogbo àwọn wọ̀nyí kì yóò máa pa òwe sí i tí wọn yóò sì máa kọ orin òwe sí i wí pé, “‘Ègbé ni fún ẹni tí ń mu ohun tí kì í ṣe tirẹ̀ pọ̀ sí i! Tí ó sì sọ ara rẹ̀ di ọlọ́rọ̀ nípasẹ̀ ìlọ́nilọ́wọ́gbà! Eléyìí yóò ha ti pẹ́ tó?’
Mon ikke alle disse skulle fremkomme imod ham med Lignelser og Tankesprog og Gaadetaler om ham? saa at man siger: Ve den, som opdynger, hvad der ej er hans! — hvor længe skal det vare —? og den, som betynger sig med Skyld!
7 Ǹjẹ́ ẹni ti ó yọ ọ́ lẹ́nu, kí yóò ha dìde ní òjijì? Àti àwọn tí ó wàhálà rẹ kì yóò jí, kí wọn ó sì dẹ́rùbà ọ́? Nígbà náà ni ìwọ yóò wa dí ìkógun fún wọn.
Skulle ikke de, som ville bide dig, pludselig staa frem, og de, som ville forstyrre dig, vaagne op, og du blive dem et Bytte?
8 Nítorí ìwọ ti kó Orílẹ̀-èdè púpọ̀, àwọn ènìyàn tókù yóò sì kó ọ nítorí ìwọ tí ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀; nítorí ẹ̀jẹ̀, ìwọ tí pa ilẹ̀ àti ìlú ńlá run àti gbogbo ènìyàn to ń gbé inú rẹ̀.
Thi du har udplyndret mange Folkefærd; dig skulle de overblevne af Folkene plyndre, for Menneskers Blods Skyld og for Voldsfærd imod Jorden, imod Staden og alle, som bo deri.
9 “Ègbé ni fún ẹni tí ń jẹ èrè ìjẹkújẹ sí ilé rẹ̀, tí o sí gbé ìtẹ́ rẹ̀ lórí ibi gíga, kí a ba le gbà á sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ibi!
Ve den, som gør sig skændig Vinding for sit Hus for at sætte sin Rede i det høje, for at redde sig fra Ulykkens Haand!
10 Ìwọ ti gbìmọ̀ ìtìjú sí ilé rẹ nípa kíké ènìyàn púpọ̀ kúrò; ìwọ sì ti pàdánù ẹ̀mí rẹ.
Du har lagt Raad op til Skam for dit Hus om at ødelægge mange Folk, idet du dog syndede imod din egen Sjæl.
11 Nítorí tí òkúta yóò kígbe jáde láti inú ògiri wá, àti ìtí igi láti inú igi rírẹ́ wá yóò sì dá a lóhùn.
Thi Stenen fra Væggen skal raabe, og Bjælken fra Træværket skal svare den.
12 “Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ẹ̀jẹ̀ kọ́ ìlú, tí o sì fi àìṣedéédéé tẹ ìlú ńlá dó?
Ve den, som bygger en By ved Blod og grundlægger en Stad ved Uret.
13 Olúwa àwọn ọmọ-ogun kò ha ti ṣètò rẹ̀ pé làálàá àwọn ènìyàn jẹ́ epo fún iná kí àwọn orílẹ̀-èdè náà sì máa ṣe wàhálà fún asán?
Se, er det ikke fra den Herre Zebaoth, at Folkene skulle gøre sig Møje for Ilden og Folkefærd arbejde sig trætte for intet?
14 Nítorí tí ayé yóò kún fún ìmọ̀ ògo Olúwa, bí omi ti bo Òkun.
Thi Jorden skal fyldes med Erkendelse af Herrens Herlighed som Vandene, der dække Havet.
15 “Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ohun mímu fún aládùúgbò rẹ̀, tí ó sì fi ọtí-lílé rẹ̀ fún un, tí o sì jẹ́ kó mu àmupara, kí ìwọ kí ó ba lè wo ìhòhò wọn.”
Ve den, som giver sin Næste en Drik, idet du blander din Vrede deri, og derhos gør dem drukne for at se paa deres Nøgenhed!
16 Ìtìjú yóò bò ọ́ dípò ògo, ìwọ náà mu pẹ̀lú kí ìhòhò rẹ kí ó lè hàn, ago ọwọ́ ọ̀tún Olúwa, yóò yípadà sí ọ, ìtìjú yóò sì bo ògo rẹ.
Du har mættet dig med Skam og ikke med Ære; saa drik da ogsaa du og lad dig se som uomskaaren! Herrens højre Haands Bæger skal vende sig til dig, og Skændsel skal være over din Herlighed.
17 Nítorí ìwà ipá tí ó tí hù sí Lebanoni yóò bò ọ́, àti ìparun àwọn ẹranko yóò dẹ́rùbà ọ́ mọ́lẹ̀. Nítorí ìwọ tí ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀; ìwọ tí pa ilẹ̀ náà àti ìlú ńlá run àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
Thi Voldsdaaden imod Libanon og Ødelæggelsen paa Dyrene, der forfærdede dem, skal bedække dig formedelst Menneskers Blod og Voldsfærd imod Jorden, imod Staden og alle dem, som bo deri.
18 “Èrè kí ni òrìṣà ni, tí oníṣọ̀nà rẹ̀ fi gbẹ́ ẹ, ère dídá ti ń kọ ni èké? Nítorí ti ẹni ti ó dá a gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé ohun tí ó fúnra rẹ̀ dá; ó sì mọ ère tí kò le fọhùn.
Hvad gavner et udskaaret Billede, at den, som dannede det, har udskaaret det? eller et støbt Billede og en Løgnens Lære, at den, som danner dens Billede, forlader sig paa den, idet han gør stumme Afguder?
19 Ègbé ni fún ẹni ti ń sọ fún igi pé, ‘Di alààyè?’ Fún òkúta tí kò lè fọhùn pé, ‘Dìde.’ Ǹjẹ́ òun lè tọ́ ni sí ọ̀nà? Wúrà àti fàdákà ni a fi bò ó yíká; kò sì sí èémí kan nínú rẹ.”
Ve den, som siger til en Træklods: Vaagn op! til en tavs Sten: Vaagn! — den skulde kunne belære? — se, den er overdragen med Guld og Sølv, og der er aldeles ingen Aand i den.
20 Ṣùgbọ́n Olúwa wà nínú tẹmpili mímọ́ rẹ̀; ẹ jẹ́ kí gbogbo ayé parọ́rọ́ níwájú rẹ.
Men Herren er i sit hellige Tempel; stille for hans Ansigt, al Jorden!