< Habakkuk 1 >

1 Àsọtẹ́lẹ̀ tí wòlíì Habakuku rí.
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri nditũ ĩrĩa yakinyĩrĩire mũnabii Habakuku.
2 Olúwa, èmi yóò ti ké pẹ́ tó fún ìrànlọ́wọ́, ṣùgbọ́n ti ìwọ kò ni fetí sí mi? Tàbí kígbe sí ọ ní ti, “Ìwà ipá!” Ṣùgbọ́n tí ìwọ kò sì gbàlà?
Wee Jehova-rĩ, nĩ nginya rĩ ngũtũũra ngũkayagĩra ũndeithie, no wee ũkaaga kũnjigua? Githĩ ndigũkayagĩra ngiugaga, “Haaro! Haaro!” no wee ũkaaga kũhonokania?
3 Èéṣe tí ìwọ fi mú mi rí àìṣedéédéé? Èéṣe tí ìwọ sì fi ààyè gba ìwà ìkà? Ìparun àti ìwà ipá wà ní iwájú mi; ìjà ń bẹ, ìkọlù sì wà pẹ̀lú.
Ũtũmaga ndĩrorere wagi wa kĩhooto nĩkĩ? Ũkiragĩrĩria maũndũ mooru nĩkĩ? Mwanangĩko na haaro irĩ mbere yakwa; kũrĩ na njũgitano, nayo mbaara nĩ nyingĩ.
4 Nítorí náà, òfin di ohun àìkàsí, ìdájọ́ òdodo kò sì borí. Àwọn ẹni búburú yí àwọn olódodo ká, nítorí náà ni ìdájọ́ òdodo ṣe yí padà.
Nĩ ũndũ ũcio, watho nĩmwagithie hinya, na kĩhooto gĩtihootanaga. Andũ arĩa aaganu marigiicaga arĩa athingu, na nĩ ũndũ ũcio kĩhooto gĩkoogomio.
5 “Ẹ wo inú àwọn kèfèrí, ki ẹ sí wòye, kí háà kí ó sì ṣe yin gidigidi. Nítorí èmi ó ṣe ohun kan ní ọjọ́ yín tí ẹ̀yin kò jẹ́ gbàgbọ́, bí a tilẹ̀ sọ fún yin.
“Atĩrĩrĩ, ta rorai ndũrĩrĩ na mwĩrorere ũhoro wacio, na mũmake biũ. Nĩgũkorwo matukũ-inĩ maku nĩngwĩka ũndũ ũrĩa ũtangĩĩtĩkia o na ũngĩĩrwo.
6 Nítorí pé, èmi yóò gbé àwọn ara Babeli dìde, àwọn aláìláàánú àti onínú-fùfù ènìyàn tí ó rin gbogbo ilẹ̀ ayé já láti fi agbára gbà àwọn ibùgbé tí kì í ṣe tiwọn.
Nĩngwarahũra andũ a Babuloni, andũ a haaro, na matarĩ tha, arĩa matuĩkanagia thĩ yothe, na makegwatĩra ciikaro itarĩ ciao.
7 Wọn jẹ́ ènìyàn ti a bẹ̀rù, tí a sì páyà, ìdájọ́ wọn, àti ọláńlá wọn, yóò máa ti inú wọn jáde.
Nĩ andũ a kũmakania, na a gwĩtigĩrwo; nĩo meyathaga, na magetũũgĩria.
8 Ẹṣin wọn yára ju ẹkùn lọ, wọ́n sì gbóná jú ìkookò àṣálẹ́ lọ àwọn ẹlẹ́ṣin wọn yóò sí tan ara wọn ká; wọn yóò sì wá láti ọ̀nà jíjìn réré, wọn yóò sí fò bí ẹyẹ igún tí ń wá láti jẹrun,
Mbarathi ciao irĩ ihenya gũkĩra ngarĩ, na nĩ ooru mũno gũkĩra njũũi iria icangacangaga kĩhwaĩ-inĩ. Thigari ciao iria ithiiaga ihaicĩte mbarathi itengʼeraga ta ciũmbũkĩte; ahaici acio a mbarathi moimaga kũndũ kũraya. Mombũkaga ta nderi ĩgĩcuuhũkĩra gĩa kũrĩa;
9 gbogbo wọn sì wà fún ìwà ipá ìwò ojú wọn yóò sì wá síwájú; wọn sì ko ìgbèkùn jọ bí iyanrìn.
othe mokaga mehaarĩirie kũruta haaro. Thigari icio ciao nyingĩ mũno ithiiaga ihaatĩte ta rũhuho rwa werũ-inĩ, igathiĩ itahĩte andũ aingĩ mũno ta mũthanga.
10 Wọn ó si máa fi àwọn ọba ṣẹ̀sín wọn ó sì tún kẹ́gàn àwọn aládé. Wọn yóò sì fi gbogbo ìlú odi alágbára nì rẹ́rìn-ín; nítorí pé, wọn yóò ko erùpẹ̀ jọ, wọn yóò sì gbà á.
Manyararaga athamaki, na makanyũrũria andũ arĩa maathanaga. Mathekagĩrĩra matũũra mothe manene marĩa mairigĩre; maakaga ihumbu cia tĩĩri, magatunyana matũũra macio.
11 Nígbà náà ni inú rẹ̀ yóò yípadà, yóò sì rékọjá, yóò si ṣẹ̀ ní kíka agbára rẹ̀ yìí sí iṣẹ́ òrìṣà rẹ̀.”
Ningĩ mahĩtũkagĩra kuo na ihenya o ta rũhuho mathiĩte na mbere: andũ maagararaga watho, magatuĩka ehia, magatua atĩ hinya wao nĩguo ngai yao.”
12 Olúwa, ǹjẹ́ láti ayérayé kọ ni ìwọ tí wà? Olúwa Ọlọ́run mi. Ẹni mímọ́ mi, àwa kì yóò kú Olúwa, ìwọ tí yàn wọn fún ìdájọ́; Ọlọ́run alágbára, ìwọ tí fi ẹsẹ̀ wọn múlẹ̀ fún ìbáwí.
Wee Jehova-rĩ, githĩ ndũtũũraga kuuma tene o na tene? O Wee Ngai wakwa, ũrĩa wakwa mũtheru, tondũ ũcio tũtigakua. Wee Jehova-rĩ, nĩwe ũthuurĩte andũ a Babuloni mahingie ituĩro rĩaku; wee Rwaro rwa Ihiga-rĩ, ũkamaamũra matũherithie.
13 Ojú rẹ mọ́ tónítóní láti wo ibi; ìwọ kò le gbà ìwà ìkà nítorí kí ni ìwọ ṣe gba àwọn alárékérekè láààyè? Nítorí kí ni ìwọ ṣe dákẹ́ nígbà tí ẹni búburú ń pa ẹni tí i ṣe olódodo ju wọn lọ run?
Maitho maku nĩ matheru mũno, matingĩĩrorera ũmaramari; wee-rĩ, ndũngĩkirĩrĩria maũndũ mooru. Ũgĩkiragĩrĩria andũ arĩa oingumania nĩkĩ? Ũkiraga nĩkĩ rĩrĩa andũ arĩa aaganu mekũmeria andũ arĩa athingu kũmakĩra?
14 Ìwọ sì tí sọ ènìyàn di bí ẹja inú Òkun, bí ohun tí ń rákò tí wọn ko ni alákòóso.
Ũtuĩte andũ ta thamaki cia iria, ũkamatua ta ciũmbe cia iria-inĩ, iria itarĩ mũciathi.
15 Àwọn ènìyàn búburú fi àwọ̀n wọn gbé wọn sókè ó sì kó wọn jọ nínú àwọ̀n ńlá rẹ̀; nítorí náà, ó dunnú, ó sì yọ̀ pẹ̀lú.
Thũ ĩyo njaganu ĩmaguucagia othe na ndwano, ĩkamagwatia na wabu wayo, ĩkamacookereria thĩinĩ wa mũtego wayo; nĩ ũndũ ũcio ĩgakena na ĩgacanjamũka.
16 Nítorí náà, ó rú ẹbọ sí àwọ̀n rẹ̀, ó sì ń sun tùràrí fún àwọ̀n ńlá rẹ̀ nítorí pẹ̀lú àwọ̀n rẹ̀ ni ó fi ń gbé ní ìgbádùn tí ó sì ń gbádùn pẹ̀lú oúnjẹ tí ó bá wù ú.
Nĩ ũndũ ũcio, ĩrutagĩra wabu wayo igongona, na ĩgacinĩra mũtego wayo ũbumba, nĩgũkorwo wabu wayo nĩguo ũtũmaga ĩtũũre ĩĩkenagia, na ĩkarĩĩaga irio iria njega mũno.
17 Ǹjẹ́ wọn yóò ha máa pa àwọ̀n wọn mọ́ ní òfìfo bí, tí wọn yóò sì pa orílẹ̀-èdè run láìsí àánú?
Ĩĩgũtũũra ĩtahaga na wabu wayo, ĩkaniinaga ndũrĩrĩ ingĩ ĩtegũciguĩra tha?

< Habakkuk 1 >