+ Genesis 1 >
1 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ohun gbogbo Ọlọ́run dá àwọn ọ̀run àti ayé.
Fefeu na, Lamatualain naꞌadadadꞌiꞌ lalai no raefafoꞌ a.
2 Ayé sì wà ní rúdurùdu, ó sì ṣófo, òkùnkùn sì wà lójú ibú omi, Ẹ̀mí Ọlọ́run sì ń rábàbà lójú omi.
Leleꞌ naa, raefafoꞌ a nda feꞌe dadꞌi sa, ma basaꞌ e feꞌe runggu-ranggaꞌ. Feꞌe akaꞌ a, oeꞌ ma maꞌahatuꞌ a tatana nala e. Lamatualain Dula-dale Na laa-laa sia oeꞌ ata.
3 Ọlọ́run sì wí pé, “Jẹ́ kí ìmọ́lẹ̀ kí ó wà,” ìmọ́lẹ̀ sì wà.
Boe ma, Lamatualain olaꞌ nae, “Manggareloꞌ dadꞌi.” Ana olaꞌ basa ma, manggareloꞌ a dadꞌi tuteꞌ a.
4 Ọlọ́run rí i pé ìmọ́lẹ̀ náà dára, ó sì ya ìmọ́lẹ̀ náà sọ́tọ̀ kúrò lára òkùnkùn.
Ana nita manggareloꞌ a ma, rala Na namahoꞌo, huu saa fo Eni taoꞌ naa, maloleꞌ. Basa de, Ana tadꞌa manggareloꞌ mia hatuꞌ a, de esa-esaꞌ no fai na.
5 Ọlọ́run sì pe ìmọ́lẹ̀ náà ní “ọ̀sán,” àti òkùnkùn ní “òru.” Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ sì jẹ́ ọjọ́ kìn-ín-ní.
Ana babꞌae manggareloꞌ a ‘rereloꞌ’, ma hatuꞌ a, ‘tetembaꞌ’. Naa, fai kaesa na.
6 Ọlọ́run sì wí pé, “Jẹ́ kí òfúrufú kí ó wà ní àárín àwọn omi, láti pààlà sí àárín àwọn omi.”
Basa ma, Lamatualain olaꞌ seluꞌ nae, “Mamana rouꞌ sa dadꞌi, fo tadꞌa oeꞌ a. Naa fo, hambu oeꞌ sia ataꞌ, ma sia raeꞌ boe.” Ana olaꞌ basa ma, oeꞌ a banggi neu rua tuteꞌ a.
7 Ọlọ́run sì dá òfúrufú láti ya omi tí ó wà ní òkè òfúrufú kúrò lára omi tí ó wà ní orí ilẹ̀. Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
8 Ọlọ́run sì pe òfúrufú ní “ọ̀run.” Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ sì jẹ́ ọjọ́ kejì.
Ana babꞌae oeꞌ mana sia ataꞌ a, ‘lalai’. Naa, fai karua na.
9 Ọlọ́run sì wí pé, “Jẹ́ kí omi abẹ́ ọ̀run wọ́ papọ̀ sí ojú kan, kí ilẹ̀ gbígbẹ sì farahàn.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Basa ma, Lamatualain olaꞌ seluꞌ fai nae, “Oe mana sia raeꞌ a musi naꞌabꞌue neu mamanaꞌ esa, fo hambu rae madꞌa.” Ana olaꞌ basa ma, rae madꞌa a dadꞌi tuteꞌ a.
10 Ọlọ́run sì pe ilẹ̀ gbígbẹ náà ní “ilẹ̀,” àti àpapọ̀ omi ní “òkun.” Ọlọ́run sì rí i wí pé ó dára.
Ana babꞌae rae madꞌa a, ‘madꞌa ata’; ma oe mana maꞌabꞌueꞌ a, ‘tasiꞌ’. Ana nita basa naa ra ma, rala Na namahoꞌo, huu saa fo Eni taoꞌ naa ra, memaꞌ maloleꞌ.
11 Ọlọ́run sì wí pé, “Jẹ́ kí ilẹ̀ kí ó hu ọ̀gbìn: ewéko ti yóò máa mú èso wá àti igi tí yóò máa so èso ní irú tirẹ̀, tí ó ní irúgbìn nínú.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Boe ma, Lamatualain olaꞌ seluꞌ fai nae, “Hau-hau musi mori sia madꞌaꞌ ata. Musi hambu hau mabꞌoaꞌ, madekeꞌ, ma maroo modꞌoꞌ. Naa fo, hau ra esa-esaꞌ mbule-bꞌoa na tungga mata na.” Ana olaꞌ basa ma, basa hau ra dadꞌi tuteꞌ a.
12 Ilẹ̀ sì hù ọ̀gbìn: ewéko tí ó ń so èso ní irú tirẹ̀, àti igi tí ń so èso, tí ó ní irúgbìn nínú ní irú tirẹ̀. Ọlọ́run sì ri pé ó dára.
Ma hau naa ra mbule-bꞌoa nara esa-esaꞌ tungga mata na, losa rasofe madꞌaꞌ ata. Ana nita basa naa ra ma, rala Na namahoꞌo, huu saa fo Eni taoꞌ naa ra, memaꞌ maloleꞌ.
13 Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ sì jẹ́ ọjọ́ kẹta.
Naa, fai katelu na.
14 Ọlọ́run sì wí pé, “Jẹ́ kí ìmọ́lẹ̀ kí ó wà ní ojú ọ̀run, láti pààlà sí àárín ọ̀sán àti òru, kí wọn ó sì máa wà fún àmì láti mọ àwọn àsìkò, àti àwọn ọjọ́ àti àwọn ọdún.
Boe ma, Lamatualain olaꞌ seluꞌ fai nae, “Sia ataꞌ musi hambu manggareloꞌ mataꞌ-mataꞌ fo raronda neu raefafoꞌ ia. Musi hambu mana fee manggareloꞌ neu fai rereloꞌ, ma mana fee manggareloꞌ neu fai tetembaꞌ. Basa naa ra, dadꞌi tatandaꞌ fo bisa reken fai, too, no fula-fai.” Ana olaꞌ basa ma, manggareloꞌ ra dadꞌi tuteꞌ a.
15 Kí wọn ó jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ní ojú ọ̀run láti tan ìmọ́lẹ̀ sí orí ilẹ̀.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
16 Ọlọ́run dá ìmọ́lẹ̀ ńlá ńlá méjì, ìmọ́lẹ̀ tí ó tóbi láti ṣe àkóso ọ̀sán àti ìmọ́lẹ̀ tí ó kéré láti ṣe àkóso òru. Ó sì dá àwọn ìràwọ̀ pẹ̀lú.
Ana tao manggarelo monaeꞌ mataꞌ rua. Manggarelo monaeꞌ a naronda rereloꞌ ma manggarelo anadikiꞌ a naronda tetembaꞌ. Ana o tao nduuꞌ ra boe.
17 Ọlọ́run sì ṣe wọ́n lọ́jọ̀ sí ojú ọ̀run láti máa tan ìmọ́lẹ̀ si orí ilẹ̀,
Ma Ana ator basa naa ra sia lalai, fo raronda neu raefafoꞌ a.
18 láti ṣàkóso ọ̀sán àti òru àti láti pààlà sí àárín ìmọ́lẹ̀ àti òkùnkùn. Ọlọ́run sì rí i pé ó dára.
De ara fee manggareloꞌ neu rereloꞌ ma tetembaꞌ. No taꞌo naa, ara tadꞌa manggareloꞌ mia hatuꞌ a. Ana nita basa naa ra ma, rala Na namahoꞌo, huu saa fo Eni taoꞌ naa ra, memaꞌ maloleꞌ.
19 Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ sì jẹ́ ọjọ́ kẹrin.
Naa, fai kahaa na.
20 Ọlọ́run sì wí pé, “Jẹ́ kí omi kí ó kún fún àwọn ohun alààyè, kí àwọn ẹyẹ kí ó sì máa fò ní òfúrufú.”
Basa ma, Lamatualain olaꞌ seluꞌ fai nae, “Banda mataꞌ-mataꞌ musi rasodꞌa sia oeꞌ rala. Ma mbuiꞌ mataꞌ-mataꞌ musi ratambembele sia raefafoꞌ ata.”
21 Nítorí náà Ọlọ́run dá àwọn ẹ̀dá alààyè ńlá ńlá sí inú òkun, àwọn ohun ẹlẹ́mìí àti àwọn ohun tí ń rìn ní onírúurú tiwọn, àti àwọn ẹyẹ abìyẹ́ ní onírúurú tiwọn. Ọlọ́run sì rí i pé ó dára.
Boe ma Ana naꞌadadadꞌiꞌ basa uꞌu mataꞌ-mataꞌ no banda monaeꞌ mana rasodꞌa sia oeꞌ. Ana o naꞌadadadꞌiꞌ mbuiꞌ mataꞌ-mataꞌ fo ratambembele sia lalai. Ana nita basa naa ra ma, rala Na namahoꞌo, huu saa fo Eni taoꞌ naa ra, memaꞌ maloleꞌ.
22 Ọlọ́run súre fún wọn, ó sì wí pé, “Ẹ máa bí sí i, ẹ sì máa pọ̀ sí i, ẹ kún inú omi òkun, kí àwọn ẹyẹ náà sì máa pọ̀ sí i ní orí ilẹ̀.”
Basa ma Ana olaꞌ fee papala-babꞌanggiꞌ neu basa banda ra nae, “Uꞌu ra musi ramaheta, fo rasofe oeꞌ a sia bee-bꞌee. Ma mbuiꞌ ra o musi ramaheta boe.”
23 Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ sì jẹ́ ọjọ́ karùn-ún.
Naa, fai kalima na.
24 Ọlọ́run sì wí pé, “Kí ilẹ̀ kí ó mú ohun alààyè jáde ní onírúurú wọn: ẹran ọ̀sìn, àwọn ohun afàyàfà àti àwọn ẹran inú igbó, ọ̀kọ̀ọ̀kan ní irú tirẹ̀.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Basa ma, Lamatualain olaꞌ seluꞌ fai nae, “Banda mataꞌ-mataꞌ musi rasodꞌa sia madꞌaꞌ ata. Musi hambu banda neꞌebꞌoiꞌ, banda fui, ma banda mana nodꞌoꞌ sia rae, esa-esaꞌ no mata na.” Ana olaꞌ basa ma, basa se dadꞌi tuteꞌ a. Ana nita basa se ma, rala Na namahoꞌo, huu saa fo Eni taoꞌ naa ra, memaꞌ maloleꞌ.
25 Ọlọ́run sì dá ẹranko inú igbó àti ẹran ọ̀sìn gbogbo ní irú tirẹ̀ àti gbogbo ohun alààyè tí ń rìn ní ilẹ̀ ní irú tirẹ̀. Ọlọ́run sì rí i pé ó dára.
26 Lẹ́yìn náà ni Ọlọ́run wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a dá ènìyàn ní àwòrán ara wa, gẹ́gẹ́ bí àwa ti rí, kí wọn kí ó jẹ ọba lórí ẹja òkun, ẹyẹ ojú ọ̀run, ẹran ọ̀sìn, gbogbo ilẹ̀ àti lórí ohun gbogbo tí ń rìn lórí ilẹ̀.”
Basa ma Lamatualain olaꞌ seluꞌ fai nae, “Ima fo Ata tao atahori tungga onaꞌ Hita boe. Naa fo, ara tao mataꞌ neu uꞌu ra sia tasi, mbuiꞌ ra sia lalai, banda neꞌeboiꞌ ra, ma basa banda feaꞌ mana masodꞌa sia raefafoꞌ a.”
27 Nítorí náà, Ọlọ́run dá ènìyàn ní àwòrán ara rẹ̀, ní àwòrán Ọlọ́run ni ó dá a, akọ àti abo ni ó dá wọn.
Boe ma Ana naꞌadadadꞌiꞌ atahori onaꞌ mata ao Na boe. Ana naꞌadadadꞌiꞌ se, touꞌ no inaꞌ.
28 Ọlọ́run sì súre fún wọn, Ọlọ́run sì wí fún wọn pé, “Ẹ máa bí sí i, kí ẹ sì máa pọ̀ sí i, kí ẹ sì gbilẹ̀, kí ẹ ṣe ìkápá ayé. Ẹ ṣe àkóso àwọn ẹja inú òkun, ẹyẹ ojú ọ̀run àti gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó ń rìn ní orí ilẹ̀.”
Ma Ana olaꞌ fee se papala-babꞌanggiꞌ nae, “Hei musi bꞌonggi mimihefu, fo misofe raefafoꞌ ia, ma tao mataꞌ neu e. Au o fee hei koasa fo tao mataꞌ neu uꞌu ra, mbuiꞌ ra, ma basa banda madꞌaꞌ ata ra.
29 Nígbà náà ni Ọlọ́run wí pé, “Mo fi gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ń so èso fún un yín bí oúnjẹ àti àwọn igi eléso pẹ̀lú. Gbogbo rẹ̀ yóò jẹ́ oúnjẹ fún un yín.
Rena malolole! Au fee hei nanaat mataꞌ-mataꞌ sia raefafoꞌ ia. Au fee hau mabꞌoaꞌ, madekeꞌ, ma maroo modꞌoꞌ ra.
30 Àti fún àwọn ẹranko inú igbó àti ẹyẹ ojú ọ̀run àti àwọn ohun afàyàfà, gbogbo ohun tó ní èémí ìyè nínú ni mo fi ewéko fún bí oúnjẹ.” Ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Au o fee basa hau mataꞌ-mataꞌ, fo dadꞌi basa banda ra nanaat na. Nanaat soaꞌ neu banda neꞌeboiꞌ, banda fui, banda mana nodꞌoꞌ, ma mbuiꞌ ra.” Ana olaꞌ basa ma, basa nanaat mataꞌ-mataꞌ dadꞌi tuteꞌ a.
31 Ọlọ́run sì rí àwọn ohun gbogbo tí ó dá, ó dára gidigidi. Àṣálẹ́ àti òwúrọ̀ sì jẹ́ ọjọ́ kẹfà.
Ana nita basa naa ra ma, rala Na namahoꞌo, huu saa fo Eni taoꞌ naa ra, memaꞌ maloleꞌ. Naa, fai kanee na.