< Genesis 9 >

1 Ọlọ́run sì súre fún Noa àti àwọn ọmọ rẹ̀ wí pé, “Ẹ máa bí sí i, kí ẹ sì pọ̀ ní iye, kí ẹ sì kún ayé.
Hĩndĩ ĩyo Ngai akĩrathima Nuhu na ariũ ake, akĩmeera atĩrĩ, “Ciaranai na mũingĩhe na mũiyũre thĩ.
2 Ẹ̀rù yín yóò mú ojo wà lára gbogbo ẹranko àti gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run, àti gbogbo àwọn ẹ̀dá tí ń rìn nílẹ̀; àti gbogbo ẹja òkun; a fi wọ́n lé e yín lọ́wọ́.
Nyamũ ciothe cia thĩ, na nyoni cia rĩera-inĩ, ciothe nĩ irĩmwĩtigagĩra na imakage nĩ inyuĩ, ciũmbe ciothe iria ithiiagĩra thĩ, na thamaki ciothe cia iria-inĩ; nĩndacineana moko-inĩ manyu.
3 Gbogbo ohun tó wà láààyè tí ó sì ń rìn, ni yóò jẹ́ oúnjẹ fún un yín, bí mo ṣe fi ewéko fún un yín náà ni mo fi ohun gbogbo fún un yín.
Kĩndũ gĩothe gĩtũũraga muoyo na gĩthiiaga-rĩ, gĩgũtuĩka irio cianyu. O ta ũrĩa ndamũheire mĩmera ĩrĩa mĩruru mũrĩĩage, rĩu nĩ ndamũhe indo ciothe ituĩke irio cianyu.
4 “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ jẹ ẹran tòun-tẹ̀jẹ̀ rẹ̀.
“No rĩrĩ, mũtikanarĩe nyama irĩ na thakame, tondũ thakame nĩyo muoyo.
5 Nítòótọ́ ẹ̀jẹ̀ yín, àní ẹ̀mí yín, ni èmi yóò sì béèrè; lọ́wọ́ gbogbo ẹranko ni èmí yóò béèrè rẹ̀, àti lọ́wọ́ ènìyàn, lọ́wọ́ arákùnrin olúkúlùkù ènìyàn ni èmi yóò béèrè ẹ̀mí ènìyàn.
Na ti-itherũ nĩngarĩhanĩria gũitwo gwa thakame yanyu. Ndĩmĩrĩhanĩrie o na kuuma kũrĩ nyamũ o na ĩrĩkũ. Nake mũndũ angĩita thakame ya mũndũ ũngĩ, o nake nĩakarĩhio thakame ĩyo.
6 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá ta ẹ̀jẹ̀ ènìyàn sílẹ̀, láti ọwọ́ ènìyàn ni a ó gbà ta ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀. Nítorí ní àwòrán Ọlọ́run ni Ọlọ́run dá ènìyàn.
“Mũndũ o wothe ũgaita thakame ya mũndũ ũngĩ, thakame yake o nayo ĩgaitwo nĩ mũndũ; nĩgũkorwo Ngai ombire mũndũ na mũhianĩre wake.
7 Ṣùgbọ́n ní tiyín, ẹ máa bí sí i, kí ẹ sì máa pọ̀ sí i, ẹ máa gbá yìn lórí ilẹ̀, kí ẹ sì pọ̀ sí i lórí rẹ̀.”
No inyuĩ-rĩ, ciaranai na mũingĩhe; muongerereke thĩ na mũiyũre kuo.”
8 Ọlọ́run sì wí fún Noa àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé,
Ningĩ Ngai akĩĩra Nuhu hamwe na ariũ ake atĩrĩ,
9 “Mo dá májẹ̀mú mi pẹ̀lú yín àti pẹ̀lú àwọn ìran yín tí ń bọ̀ lẹ́yìn.
“Rĩu niĩ nĩngũthondeka kĩrĩkanĩro gĩakwa na inyuĩ, na njiaro cianyu iria igooka thuutha wanyu,
10 Àti pẹ̀lú gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó wà pẹ̀lú yín, ìbá à ṣe ẹyẹ, ẹja, ẹran ọ̀sìn, ẹranko igbó, gbogbo ohun tí ó jáde kúrò nínú ọkọ̀ pẹ̀lú yín, àní gbogbo ẹ̀dá alààyè ní ayé.
o na hamwe na kĩũmbe gĩothe kĩrĩ muoyo kĩa iria mũraarĩ nacio; nĩcio nyoni, na mahiũ o na nyamũ cia gĩthaka ciothe iria cioimire thabina hamwe na inyuĩ, ici nĩcio ciũmbe ciothe irĩ muoyo gũkũ thĩ.
11 Mo dá májẹ̀mú mi pẹ̀lú yín láéláé, Èmi kì yóò fi ìkún omi pa ayé run kúrò mọ láéláé, a kì yóò fi omi pa ayé run.”
Nĩndathondeka kĩrĩkanĩro gĩakwa na inyuĩ: Gũtirĩ hĩndĩ ĩngĩ muoyo wothe ũkaaniinwo na mũiyũro wa maaĩ; gũtirĩ hĩndĩ ĩngĩ gũkaagĩa mũiyũro wa maaĩ wa kũniina thĩ.”
12 Ọlọ́run sì wí pé, “Èyí ni àmì májẹ̀mú tí mo ń dá yìí láàrín èmi àti ẹ̀yin àti ẹ̀dá alààyè tí ó wà pẹ̀lú yín, májẹ̀mú àtìrandíran tó ń bọ̀:
Ningĩ Ngai akiuga atĩrĩ, “Gĩkĩ nĩkĩo kĩmenyithia gĩa kĩrĩkanĩro kĩrĩa ndĩrarĩkanĩra na inyuĩ na ciũmbe ciothe irĩ muoyo irĩ hamwe na inyuĩ, kĩrĩkanĩro kĩa njiarwa ciothe iria igooka:
13 Mo ti fi òṣùmàrè sí àwọsánmọ̀, yóò sì jẹ́ àmì májẹ̀mú láàrín èmi àti ayé.
Nĩndekĩra mũkũnga-mbura wakwa matu-inĩ, na nĩguo ũgũtuĩka kĩmenyithia gĩa kĩrĩkanĩro gatagatĩ gakwa na andũ a thĩ.
14 Nígbàkígbà tí mo bá mú kí òjò ṣú, tí òṣùmàrè bá farahàn ní àwọsánmọ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa yothe ngaarehe matu igũrũ rĩa thĩ, naguo mũkũnga-mbura woneke matu-inĩ macio,
15 Èmi yóò rántí májẹ̀mú mi, tí ó wà láàrín èmi àti ẹ̀yin àti gbogbo ẹ̀dá alààyè, kì yóò sì tún sí ìkún omi mọ́ láti pa gbogbo ẹ̀dá run.
nĩndĩĩririkanaga kĩrĩkanĩro gĩakwa gatagatĩ kanyu na niĩ, na gatagatĩ ga ciũmbe cia mĩthemba yothe iria itũũraga muoyo. Gũtirĩ hĩndĩ ĩngĩ maaĩ magatuĩka mũiyũro wa kũniina mĩoyo yothe.
16 Nígbàkígbà tí òṣùmàrè bá yọ ní àwọsánmọ̀, èmi yóò rí i, èmi yóò sì rántí májẹ̀mú ayérayé tí ń bẹ láàrín Ọlọ́run àti gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ń bẹ ní ayé.”
Rĩrĩa rĩothe mũkũnga-mbura ũrĩonekaga itu-inĩ-rĩ, ndĩĩwonaga ngaririkana kĩrĩkanĩro kĩrĩa gĩa gũtũũra nginya tene gatagatĩ ka Ngai na ciũmbe cia mĩthemba yothe iria itũũraga muoyo gũkũ thĩ.”
17 Ọlọ́run sì wí fún Noa pé, “Èyí ni àmì májẹ̀mú tí mo ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ láàrín èmi àti gbogbo alààyè ní ayé.”
Nĩ ũndũ ũcio Ngai akĩĩra Nuhu atĩrĩ, “Gĩkĩ nĩkĩo kĩmenyithia gĩa kĩrĩkanĩro kĩrĩa ndathondeka gatagatĩ gakwa na kĩndũ gĩothe kĩrĩ muoyo gũkũ thĩ.”
18 Àwọn ọmọ Noa tí ó jáde nínú ọkọ̀ ni Ṣemu, Hamu àti Jafeti. (Hamu ni baba Kenaani.)
Ariũ a Nuhu arĩa moimire thabina maarĩ Shemu, na Hamu na Jafethu. (Hamu nĩwe warĩ ithe wa Kaanani).
19 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Noa mẹ́tẹ̀ẹ̀ta yìí ni gbogbo ènìyàn ti tàn ká gbogbo ilẹ̀ ayé.
Acio atatũ nĩo maarĩ ariũ a Nuhu, na kuuma kũrĩ o gũkiuma andũ arĩa othe maahurunjirwo thĩ yothe.
20 Noa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ àgbẹ̀, ó sì gbin ọgbà àjàrà.
Nuhu aarĩ mũrĩmi, na nĩahaandire mũgũnda wa mĩthabibũ.
21 Ó mu àmupara nínú ọtí wáìnì àjàrà rẹ̀, ó sì tú ara rẹ̀ sí ìhòhò, ó sì sùn nínú àgọ́ rẹ̀.
Rĩrĩa aanyuire ndibei ya mĩthabibũ ĩyo, akĩrĩĩo, na agĩkoma thĩinĩ wa hema yake atehumbĩrĩte.
22 Hamu tí í ṣe baba Kenaani sì rí baba rẹ̀ ní ìhòhò bẹ́ẹ̀ ni ó sì lọ sọ fún àwọn arákùnrin rẹ̀ méjèèjì ní ìta.
Hamu, ithe wa Kaanani, nĩonire njaga ya ithe, na akĩĩra ariũ a nyina eerĩ arĩa maarĩ nja.
23 Ṣùgbọ́n Ṣemu àti Jafeti mú aṣọ lé èjìká wọn, wọ́n sì fi ẹ̀yìn rìn, wọ́n sì bo ìhòhò baba wọn. Wọ́n kọjú sẹ́yìn kí wọn kí ó má ba à rí ìhòhò baba wọn.
No Shemu na Jafethu makĩoya nguo makĩigĩrĩra ciande; magĩthiĩ na kĩĩhutaatĩ, makĩhumbĩra njaga ya ithe. Mothiũ mao maahũgũkĩte na kũngĩ nĩguo matikoone njaga ya ithe wao.
24 Nígbà tí Noa kúrò ní ojú ọtí, tí ó sì mọ ohun tí ọmọ rẹ̀ kékeré ṣe sí i.
Rĩrĩa Nuhu aarĩĩũkirwo na akĩmenya ũrĩa mũriũ wake ũrĩa mũnini aamwĩkĩte-rĩ,
25 Ó wí pé, “Ègún ni fún Kenaani. Ìránṣẹ́ àwọn ìránṣẹ́ ni yóò máa ṣe fún àwọn arákùnrin rẹ̀.”
akiuga atĩrĩ, “Kaanani aronyiitwo nĩ kĩrumi! Agaatuĩka ngombo ya kũhinyĩrĩrio biũ nĩ ariũ a nyina.”
26 Ó sì tún wí pé, “Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Ṣemu Kenaani yóò máa ṣe ẹrú fún Ṣemu.
Ningĩ akiuga atĩrĩ, “Jehova arogaathwo, o we Ngai wa Shemu! Kaanani arotuĩka ngombo ya Shemu.
27 Ọlọ́run yóò mú Jafeti gbilẹ̀, Jafeti yóò máa gbé ní àgọ́ Ṣemu Kenaani yóò sì jẹ́ ẹrú fún un.”
Ngai aroaramia mĩhaka ya Jafethu; Jafethu arotũũra hema-inĩ cia Shemu, na Kaanani arotuĩka ngombo yake.”
28 Noa wà láààyè fún irinwó ọdún dín àádọ́ta lẹ́yìn ìkún omi.
Thuutha wa mũiyũro wa maaĩ gũthira-rĩ, Nuhu aatũũrire muoyo mĩaka magana matatũ na mĩrongo ĩtano.
29 Àpapọ̀ ọjọ́ ayé Noa jẹ́ ẹgbẹ̀rún ọdún dín làádọ́ta, ó sì kú.
Mĩaka yothe ĩrĩa Nuhu aatũũrire muoyo yarĩ mĩaka magana kenda na mĩrongo ĩtano, agĩcooka agĩkua.

< Genesis 9 >