< Genesis 6 >

1 Nígbà tí ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí ní pọ̀ si ní orí ilẹ̀, wọ́n sí bí àwọn ọmọbìnrin.
A I ka wa o ka hoomaka ana e mahuahua ai na kanaka maluna o ka honua, a ua hanau mai na kaikamahine a lakou.
2 Àwọn ọmọ Ọlọ́run rí i wí pé àwọn ọmọbìnrin ènìyàn lẹ́wà, wọ́n sì fẹ́ èyíkéyìí tí ó wù wọ́n ṣe aya.
Ike ae la na keiki a ke Akua i na kaikamahine a na kanaka, ua maikai lakou; lalau aku la lakou i na mea a lakou i makemake ai i mau wahine na lakou.
3 Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Èémí ìyè tí mo mí sínú ènìyàn kò ní máa gbé inú ènìyàn títí láé, nítorí ẹran-ara sá à ni òun, ọgọ́fà ọdún ni ọjọ́ rẹ̀ yóò jẹ́.”
I iho la o Iehova, Aole e noho loa ana kuu Uhane me kanaka, no ka mea, he kino no ia; aku, o kona mau la ma keia hope aku, he haneri makahiki ia a me ka iwakalua.
4 Àwọn òmíràn wà láyé ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àti lẹ́yìn ìgbà náà; nígbà tí àwọn ọmọ Ọlọ́run lọ bá àwọn ọmọbìnrin ènìyàn lòpọ̀ tí wọ́n sì bímọ fún wọn. Àwọn náà ni ó di akọni àti olókìkí ìgbà náà.
Noho iho la na kanaka nunui ma ka honua ia manawa; a mahope aku, a komo aku la na keiki a ke Akua iloko i na kaikamahine a na kanaka, a hanau mai na lakou ka poe kanaka ikaika, he poe kanaka kaulana lakou i ka wa kahiko.
5 Olúwa sì rí bí ìwà búburú ènìyàn ti ń gbilẹ̀ si, àti pé gbogbo èrò inú rẹ̀ kìkì ibi ni, ní ìgbà gbogbo.
A ike mai la ke Akua, he nui ka hewa o kanaka ma ka honua, a ua hewa wale no ka noonoo ana o kona naau, ana i manao ai i na la a pau.
6 Inú Olúwa sì bàjẹ́ gidigidi nítorí pé ó dá ènìyàn sí ayé, ọkàn rẹ̀ sì gbọgbẹ́.
A mihi iho la o Iehova i kana hana ana i na kanaka maluna o ka honua, a ua ehaeha kona naau.
7 Nítorí náà, Olúwa wí pé, “Èmi yóò pa ènìyàn tí mo ti dá run kúrò lórí ilẹ̀, ènìyàn àti ẹranko, àti ohun tí ń rákò, àti ẹyẹ ojú ọ̀run, nítorí inú mi bàjẹ́ pé mo ti dá wọn.”
I iho la o Iehova, E luku auanei au i na kanaka a'u i hana'i, mai ke alo aku o ka honua, i na kanaka a me na holoholona, a me na mea kolo, a me na manu o ka lewa: no ka mea, ke mihi nei au i ka'u hana ana ia lakou:
8 Ṣùgbọ́n, Noa rí ojúrere Olúwa.
Aka, loaa ia Noa ke alohaia mai imua o Iehova.
9 Wọ̀nyí ni ìtàn Noa. Noa nìkan ni ó jẹ́ olóòótọ́ ènìyàn àti ẹni tí ó pé ní ìgbà ayé rẹ̀, ó sì fi òtítọ́ bá Ọlọ́run rìn.
Eia ka mooolelo no Noa: He kanaka pono o Noa, a he hemolele iwaena o na hanauna ona, a hele pu o Noa me ke Akua.
10 Noa sì bí ọmọkùnrin mẹ́ta, Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
Ua hanau mai na Noa ekolu keikikane, o Sema, o Hama, a o Iapeta.
11 Ayé sì kún fún ìbàjẹ́ gidigidi ní ojú Ọlọ́run, ó sì kún fún ìwà ipá pẹ̀lú.
Ua inoino hoi ka honua imua o ke Akua; a ua piha ka honua i ka hoino.
12 Ọlọ́run sì rí bí ayé ti bàjẹ́ tó, nítorí àwọn ènìyàn inú ayé ti bá ara wọn jẹ́ ní gbogbo ọ̀nà wọn.
Nana mai la ke Akua i ka honua, aia hoi, ua inoino ia; no ka mea, ua hana ino na kanaka a pau i ko lakou aoao ma ka honua.
13 Ọlọ́run sì wí fún Noa pé, “Èmi yóò pa gbogbo ènìyàn run, nítorí ilẹ̀ ayé kún fún ìwà ipá nípasẹ̀ wọn. Èmi yóò pa wọ́n run àti ayé pẹ̀lú.
Olelo mai la o Iehova ia Noa, Ua hiki mai i ko'u alo nei ka hope o na mea ola a pau; no ka mea, ua piha ka honua i ka hoino ma o lakou la: aia hoi, e luku auanei au ia lakou ma ka honua.
14 Nítorí náà fi igi ọ̀mọ̀ kan ọkọ̀, kí o sì yọ yàrá sí inú rẹ̀, kí o sì fi ọ̀dà ilẹ̀ rẹ́ ẹ tinú-tẹ̀yìn.
E hana oe i halelana nou; e hana hoi oe i na keena maloko o ka halelana, a e hapala ae i ke kepau maloko a mawaho.
15 Báyìí ni ìwọ yóò ṣe kan ọkọ̀ náà: Gígùn rẹ̀ ní òró yóò jẹ́ ọ̀ọ́dúnrún ìgbọ̀nwọ́, ìbú rẹ̀ yóò jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́, nígbà tí gíga rẹ̀ yóò jẹ́ ọgbọ̀n ìgbọ̀nwọ́.
Penei kau e hana aku ai: ekolu haneri kubita o ka loa o ka halelana, he kanalima na kubita ka laula, a he kanakolu na kubita o kona kiekie.
16 Ṣe òrùlé sí orí ọkọ̀ náà ní ìgbọ̀nwọ́ kan, sì ṣe ọkọ̀ náà ní alájà mẹ́ta, ipá kan ní ìsàlẹ̀, ọ̀kan ní àárín àti ọ̀kan tí ó kù ní òkè, ẹ̀gbẹ́ ni kí ó ṣe ẹnu-ọ̀nà ọkọ̀ náà sí.
He malamalama kau e hana'i ma ka halelana, a e hoopaa ia mea maluna ma ke kubita; a e kau oe i ka pukakomo o ka halelana ma kona paia: a he papalalo, me ka papawaena, a me ka papaluna kau e hana'i ma ia mea.
17 Èmi yóò mú ìkún omi wá sí ayé láti pa gbogbo ohun ẹlẹ́mìí run lábẹ́ ọ̀run. Gbogbo ẹ̀dá tí ó ní èémí ìyè ní inú. Gbogbo ohun tí ó wà nínú ayé yóò parun.
A owau la e, e lawe mai ana au i ke kaiakahinalii maluna o ka honua, i mea e lukuia'i na mea io a pau, i ka poe nona ka hanu ola malalo o ka lani; a e make na mea a pau ma ka honua.
18 Ṣùgbọ́n èmi ó dá májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ, ìwọ yóò sì wọ ọkọ̀, ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ pẹ̀lú aya rẹ.
Aka, e hoopaa aku au i ka'u berita ia oe; a e komo ae oe iloko o ka halelana, o oe, me kau mau keikikane, a me kau wahine, a me na wahine a kau mau keikikane.
19 Ìwọ yóò mú gbogbo ohun alààyè takọ tabo wá sí inú ọkọ̀, kí wọn le wà láààyè pẹ̀lú rẹ.
A no na mea io a pau e ola ana, e lawe oe i elua o kela mea keia mea iloko o ka halelana, i kane i wahine, i malama ola pu ia lakou me oe.
20 Mú onírúurú àwọn ẹyẹ, ẹranko àti àwọn ohun tí ń rákò ní méjì méjì, kí a bá lè pa wọ́n mọ́ láààyè.
O na manu ma ko lakou ano, a o na holoholona, ma ko lakou ano, a o kela mea kolo keia mea kolo o ka honua, ma kona ano iho, e hele papalua mai lakou iou la, i malama ola ia lakou.
21 Mú onírúurú oúnjẹ wá sínú ọkọ̀, kí o pa wọ́n mọ́ fún jíjẹ gbogbo ẹ̀yin tí ẹ wà nínú ọkọ̀ àti ènìyàn àti ẹranko.”
E lawe oe nau i na mea ai a pau, a e hoiliili oe ia iou la; i mea ai nau, a na lakou.
22 Noa sì ṣe ohun gbogbo bí Ọlọ́run ti pàṣẹ fún un.
Pela o Noa i hana'i; ma ka mea a pau a ke Akua i kauoha mai ai ia ia, pela oia i hana'i.

< Genesis 6 >

The World is Destroyed by Water
The World is Destroyed by Water