< Genesis 6 >

1 Nígbà tí ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí ní pọ̀ si ní orí ilẹ̀, wọ́n sí bí àwọn ọmọbìnrin.
Rĩrĩa andũ maambĩrĩirie kũingĩha thĩ na magĩciarĩrwo airĩtu-rĩ,
2 Àwọn ọmọ Ọlọ́run rí i wí pé àwọn ọmọbìnrin ènìyàn lẹ́wà, wọ́n sì fẹ́ èyíkéyìí tí ó wù wọ́n ṣe aya.
ariũ a Ngai makĩona atĩ airĩtu a andũ maarĩ athaka, nao makĩhikia o ũrĩa mũndũ ethuuragĩra.
3 Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Èémí ìyè tí mo mí sínú ènìyàn kò ní máa gbé inú ènìyàn títí láé, nítorí ẹran-ara sá à ni òun, ọgọ́fà ọdún ni ọjọ́ rẹ̀ yóò jẹ́.”
Nake Jehova akiuga atĩrĩ, “Roho wakwa ndegũtũũra agianaga na mũndũ nginya tene, tondũ mũndũ nĩ wa gũkua; matukũ make marĩkoragwo marĩ mĩaka igana na mĩrongo ĩĩrĩ.”
4 Àwọn òmíràn wà láyé ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àti lẹ́yìn ìgbà náà; nígbà tí àwọn ọmọ Ọlọ́run lọ bá àwọn ọmọbìnrin ènìyàn lòpọ̀ tí wọ́n sì bímọ fún wọn. Àwọn náà ni ó di akọni àti olókìkí ìgbà náà.
Na rĩrĩ, matukũ-inĩ macio, o na thuutha ũcio, rĩrĩa Anefili matũũraga gũkũ thĩ, nĩrĩo ariũ a Ngai maakomire na airĩtu a andũ na magĩciara ciana nao. Ciana icio nĩcio ciarĩ njamba cia tene na andũ arĩa maarĩ igweta.
5 Olúwa sì rí bí ìwà búburú ènìyàn ti ń gbilẹ̀ si, àti pé gbogbo èrò inú rẹ̀ kìkì ibi ni, ní ìgbà gbogbo.
Jehova akĩona ũrĩa waganu wa andũ waingĩhĩte gũkũ thĩ, na atĩ merirĩria ma meciiria ma ngoro ciao maarĩ mooru hĩndĩ ciothe.
6 Inú Olúwa sì bàjẹ́ gidigidi nítorí pé ó dá ènìyàn sí ayé, ọkàn rẹ̀ sì gbọgbẹ́.
Jehova akĩnyiitwo nĩ kĩeha nĩ ũndũ wa kũũmba mũndũ gũkũ thĩ, na ngoro yake ĩkĩiyũrwo nĩ ruo.
7 Nítorí náà, Olúwa wí pé, “Èmi yóò pa ènìyàn tí mo ti dá run kúrò lórí ilẹ̀, ènìyàn àti ẹranko, àti ohun tí ń rákò, àti ẹyẹ ojú ọ̀run, nítorí inú mi bàjẹ́ pé mo ti dá wọn.”
Nĩ ũndũ ũcio Jehova akiuga atĩrĩ, “Nĩngũniina andũ, o arĩa niĩ ndombire, mathire kuuma thĩ, andũ na nyamũ, na ciũmbe iria ithiiagĩra thĩ, o na nyoni cia rĩera-inĩ, nĩgũkorwo ndĩ na kĩeha nĩ ũndũ wa gũciũmba.”
8 Ṣùgbọ́n, Noa rí ojúrere Olúwa.
No Nuhu agĩĩtĩkĩrĩka maitho-inĩ ma Jehova.
9 Wọ̀nyí ni ìtàn Noa. Noa nìkan ni ó jẹ́ olóòótọ́ ènìyàn àti ẹni tí ó pé ní ìgbà ayé rẹ̀, ó sì fi òtítọ́ bá Ọlọ́run rìn.
Ũyũ nĩguo ũhoro wa Nuhu. Nuhu aarĩ mũndũ mũthingu, ũtaarĩ na ũcuuke kũrĩ andũ a hĩndĩ yake, na nĩatwaranaga na Ngai.
10 Noa sì bí ọmọkùnrin mẹ́ta, Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
Nuhu aarĩ na ariũ atatũ: nĩo Shemu, na Hamu na Jafethu.
11 Ayé sì kún fún ìbàjẹ́ gidigidi ní ojú Ọlọ́run, ó sì kún fún ìwà ipá pẹ̀lú.
Thĩ nayo yarĩ thũku maitho-inĩ ma Jehova na yaiyũrĩtwo nĩ maũndũ ma ũhinya.
12 Ọlọ́run sì rí bí ayé ti bàjẹ́ tó, nítorí àwọn ènìyàn inú ayé ti bá ara wọn jẹ́ ní gbogbo ọ̀nà wọn.
Ngai nĩonire ũrĩa thĩ yathũkĩte, nĩgũkorwo andũ othe a thĩ nĩmathũkĩtie mĩthiĩre yao.
13 Ọlọ́run sì wí fún Noa pé, “Èmi yóò pa gbogbo ènìyàn run, nítorí ilẹ̀ ayé kún fún ìwà ipá nípasẹ̀ wọn. Èmi yóò pa wọ́n run àti ayé pẹ̀lú.
Nĩ ũndũ ũcio Jehova akĩĩra Nuhu atĩrĩ, “Nĩnduĩte itua kũniina andũ aya othe, nĩgũkorwo thĩ nĩ ĩiyũrĩtwo nĩ maũndũ ma ũhinya nĩ ũndũ wao. Ti-itherũ nĩngũmaniinanĩria hamwe na thĩ.
14 Nítorí náà fi igi ọ̀mọ̀ kan ọkọ̀, kí o sì yọ yàrá sí inú rẹ̀, kí o sì fi ọ̀dà ilẹ̀ rẹ́ ẹ tinú-tẹ̀yìn.
Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, wĩyakĩre thabina ya mĩtĩ ya mĩthithinda; na ũthondeke tũnyũmba thĩinĩ, na ũmĩhake rami thĩinĩ na nja.
15 Báyìí ni ìwọ yóò ṣe kan ọkọ̀ náà: Gígùn rẹ̀ ní òró yóò jẹ́ ọ̀ọ́dúnrún ìgbọ̀nwọ́, ìbú rẹ̀ yóò jẹ́ àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́, nígbà tí gíga rẹ̀ yóò jẹ́ ọgbọ̀n ìgbọ̀nwọ́.
Na ũkũmĩaka ũũ: Ũraihu wa thabina ũkorwo ũrĩ buti magana mana na mĩrongo ĩtano, na wariĩ wa buti mĩrongo mũgwanja na ithano na buti mĩrongo ĩna na ithano, kũraiha na igũrũ.
16 Ṣe òrùlé sí orí ọkọ̀ náà ní ìgbọ̀nwọ́ kan, sì ṣe ọkọ̀ náà ní alájà mẹ́ta, ipá kan ní ìsàlẹ̀, ọ̀kan ní àárín àti ọ̀kan tí ó kù ní òkè, ẹ̀gbẹ́ ni kí ó ṣe ẹnu-ọ̀nà ọkọ̀ náà sí.
Ũmĩgite igũrũ, no ũtigie buti ĩmwe na nuthu mwena wa igũrũ wa thingo. Wĩkĩre mũrango mwena-inĩ wa thabina, na ũmĩake ĩrĩ na ngoroba ya thĩ, na ya gatagatĩ, na ya igũrũ.
17 Èmi yóò mú ìkún omi wá sí ayé láti pa gbogbo ohun ẹlẹ́mìí run lábẹ́ ọ̀run. Gbogbo ẹ̀dá tí ó ní èémí ìyè ní inú. Gbogbo ohun tí ó wà nínú ayé yóò parun.
Nĩngũrehe mũiyũro wa maaĩ gũkũ thĩ wa kũniina kĩndũ gĩothe kĩrĩ muoyo gũkũ thĩ, kĩũmbe o gĩothe kĩrĩ na mĩhũmũ ya muoyo thĩinĩ wakĩo. Indo ciothe irĩ thĩ nĩikũniinwo.
18 Ṣùgbọ́n èmi ó dá májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ, ìwọ yóò sì wọ ọkọ̀, ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ pẹ̀lú aya rẹ.
No nĩngũthondeka kĩrĩkanĩro nawe. Wee nĩũgatoonya thabina, wee mwene na ariũ aku na mũtumia waku, na atumia a ariũ aku.
19 Ìwọ yóò mú gbogbo ohun alààyè takọ tabo wá sí inú ọkọ̀, kí wọn le wà láààyè pẹ̀lú rẹ.
Ningĩ nĩũkaingĩria ciũmbe cia mĩthemba yothe thĩinĩ wa thabina, o mũthemba ciũmbe igĩrĩ, wa njamba na wa nga, nĩguo itũũre muoyo, o hamwe nawe.
20 Mú onírúurú àwọn ẹyẹ, ẹranko àti àwọn ohun tí ń rákò ní méjì méjì, kí a bá lè pa wọ́n mọ́ láààyè.
O mũthemba wa nyoni, na o mũthemba wa nyamũ ciothe na ciũmbe ciothe iria ithiiagĩra thĩ, nĩigooka kũrĩ we igĩrĩ igĩrĩ nĩguo itũũre muoyo.
21 Mú onírúurú oúnjẹ wá sínú ọkọ̀, kí o pa wọ́n mọ́ fún jíjẹ gbogbo ẹ̀yin tí ẹ wà nínú ọkọ̀ àti ènìyàn àti ẹranko.”
Nĩũkamaatha mĩthemba yothe ya irio iria irĩĩagwo, ũciige irĩ irio ciaku na ciacio.”
22 Noa sì ṣe ohun gbogbo bí Ọlọ́run ti pàṣẹ fún un.
Nuhu agĩĩka maũndũ mothe o ta ũrĩa Ngai aamwathĩte eeke.

< Genesis 6 >

The World is Destroyed by Water
The World is Destroyed by Water