< Genesis 46 >
1 Báyìí ni Israẹli mú ìrìnàjò rẹ̀ pọ̀n pẹ̀lú ohun gbogbo tí ó ní, nígbà tí ó sì dé Beerṣeba, ó rú ẹbọ sí Ọlọ́run Isaaki baba rẹ̀.
Xuning bilǝn Israil barliⱪ tǝǝlluⱪatini elip yolƣa qiⱪip, Bǝǝr-Xebaƣa kǝldi. U xu yǝrdǝ atisi Isⱨaⱪning Hudasiƣa ⱪurbanliⱪlarni sundi.
2 Ọlọ́run sì bá Israẹli sọ̀rọ̀ ní ojú ìran ní òru pé, “Jakọbu! Jakọbu!” Ó sì dáhùn pé, “Èmi nìyí.”
Keqisi Huda alamǝt kɵrünüxlǝrdǝ Israilƣa: — Yaⱪup, Yaⱪup! dewidi, u jawab berip: — Mana mǝn! — dedi.
3 Ọlọ́run sì wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run, Ọlọ́run baba rẹ, má ṣe bẹ̀rù láti sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilẹ̀ Ejibiti nítorí, èmi yóò sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá níbẹ̀.
U: — Atangning Tǝngrisi bolƣan Huda Mǝndurmǝn. Sǝn Misirƣa berixtin ⱪorⱪmiƣin, qünki Mǝn seni xu yǝrdǝ uluƣ bir ⱪowm ⱪilimǝn.
4 Èmi yóò sì sọ̀kalẹ̀ pẹ̀lú rẹ lọ sí Ejibiti, èmi yóò sì tún mú ọ padà wá. Ọwọ́ Josẹfu fúnra rẹ̀ ni ìwọ yóò sì kú sí.”
Mǝn sening bilǝn Misirƣa billǝ barimǝn wǝ Mǝn Ɵzüm jǝzmǝn yǝnǝ seni xu yǝrdin yandurup kelimǝn. Yüsüp ɵz ⱪoli bilǝn sening kɵzüngni yumduridu, — dedi.
5 Nígbà náà ni Jakọbu kúrò ní Beerṣeba, àwọn ọmọ Israẹli sì mú Jakọbu baba wọn àti àwọn aya wọn àti àwọn ọmọ wọn, wọ́n sì kó wọn sí inú kẹ̀kẹ́ ẹrù tí Farao fi ránṣẹ́ fún ìrìnàjò rẹ̀.
Andin Yaⱪup Bǝǝr-Xebadin yolƣa qiⱪti; Israilning oƣulliri atisi Yaⱪup wǝ ularning bala-qaⱪilirini Pirǝwn uni epkelix üqün ǝwǝtkǝn ⱨarwilarƣa olturƣuzup,
6 Wọ́n tún kó àwọn ohun ọ̀sìn wọn àti gbogbo ohun ìní tí wọ́n ti ní láti ilẹ̀ Kenaani, Jakọbu àti gbogbo irú-ọmọ rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti.
qarpayliri bilǝn Ⱪanaan zeminida tapⱪan tǝǝlluⱪatlirini elip mangdi. Bu tǝriⱪidǝ Yaⱪup bilǝn barliⱪ ǝwladliri Misirƣa kǝldi; oƣullirini, oƣul nǝwrilirini, ⱪizlirini, ⱪiz nǝwrilirini yiƣip, nǝsillirining ⱨǝmmisini ɵzi bilǝn billǝ elip Misirƣa kǝldi.
7 Ó kó àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin pẹ̀lú àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin pẹ̀lú àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ obìnrin, gbogbo irú-ọmọ rẹ̀ lọ sí Ejibiti.
8 Èyí ni orúkọ àwọn ọmọ Israẹli (Jakọbu àti ìran rẹ̀) tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ Ejibiti: Reubeni àkọ́bí Jakọbu.
Israilning oƣulliri, yǝni Yaⱪupning Misirƣa kǝlgǝn ǝwladliri tɵwǝndikiqǝ: — Yaⱪupning tunji oƣli Rubǝn;
9 Àwọn ọmọkùnrin Reubeni: Hanoku, Pallu, Hesroni àti Karmi.
Rubǝnning oƣulliri Ⱨanoh, Pallu, Ⱨǝzron bilǝn Karmi.
10 Àwọn ọmọkùnrin Simeoni: Jemueli, Jamini, Ohadi, Jakini, Sohari àti Saulu, tí ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọbìnrin ará Kenaani.
Ximeonning oƣulliri: — Yǝmuǝl, Yamin, Oⱨad, Yaⱪin, Zoⱨar wǝ Ⱪanaaniy ayaldin bolƣan Saul.
11 Àwọn ọmọkùnrin Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.
Lawiyning oƣulliri: — Gǝrxon, Koⱨat wǝ Mǝrari.
12 Àwọn ọmọkùnrin Juda: Eri, Onani, Ṣela, Peresi àti Sera (ṣùgbọ́n Ẹri àti Onani ti kú ní ilẹ̀ Kenaani). Àwọn ọmọ Peresi: Hesroni àti Hamulu.
Yǝⱨudaning oƣulliri: — Ər, Onan, Xǝlaⱨ, Pǝrǝz wǝ Zǝraⱨ. Əmma Ər wǝ Onan Ⱪanaanning zeminida ɵlüp kǝtkǝnidi. Pǝrǝzning oƣulliri Ⱨǝzron bilǝn Ⱨamullar idi.
13 Àwọn ọmọkùnrin: Isakari! Tola, Pua, Jaṣibu àti Ṣimroni.
Issakarning oƣulliri: — Tola, Puaⱨ, Yob wǝ Ximron.
14 Àwọn ọmọkùnrin Sebuluni: Seredi, Eloni àti Jahaleli.
Zǝbulunning oƣulliri: — Sǝrǝd, Elon wǝ Jaⱨliyǝl.
15 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin Lea tí ó bí fún Jakọbu ní Padani-Aramu yàtọ̀ fún Dina ọmọbìnrin rẹ̀. Àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ àti ọmọbìnrin rẹ̀ wọ̀nyí jẹ́ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n lápapọ̀.
Bular Leyaⱨning Yaⱪupⱪa Padan-Aramda tuƣup bǝrgǝn oƣul-ǝwladliri idi; u yǝnǝ ⱪizi Dinaⱨni tuƣup bǝrdi. Buning bu oƣul-ⱪiz pǝrzǝntliri jǝmiy bolup ottuz üq jan idi.
16 Àwọn ọmọkùnrin Gadi: Sefoni, Haggi, Ṣuni, Esboni, Eri, Arodi, àti Areli.
Gadning oƣulliri: — Zifion, Ⱨaggi, Xuni, Əzbon, Eri, Arodi wǝ Arǝli.
17 Àwọn ọmọkùnrin Aṣeri: Imina, Iṣifa, Iṣfi àti Beriah. Arábìnrin wọn ni Sera. Àwọn ọmọkùnrin Beriah: Heberi àti Malkieli.
Axirning oƣulliri: — Yimnaⱨ, Yixwaⱨ, Yixwi wǝ Beriyaⱨ. Ularning singlisi Seraⱨ idi; Beriyaⱨning oƣulliri Ⱨǝbǝr wǝ Malkiǝl idi.
18 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ tí Jakọbu bí nípasẹ̀ Silipa, ẹni tí Labani fi fún Lea ọmọbìnrin rẹ̀. Gbogbo wọn jẹ́ mẹ́rìndínlógún lápapọ̀.
Bular bolsa Laban ⱪizi Leyaⱨⱪa dedǝk boluxⱪa bǝrgǝn Zilpaⱨning Yaⱪupⱪa tuƣup bǝrgǝn oƣulliri bolup, jǝmiy on altǝ jan idi.
19 Àwọn ọmọkùnrin Rakeli aya Jakọbu: Josẹfu àti Benjamini.
Yaⱪupning ayali Raⱨilǝning oƣulliri Yüsüp wǝ Binyamin.
20 Ní Ejibiti, Asenati ọmọbìnrin Potifẹra, alábojútó àti àlùfáà Oni, bí Manase àti Efraimu fún Josẹfu.
Yüsüpkǝ Misir zeminida tɵrǝlgǝn oƣulliri Manassǝⱨ wǝ Əfraim; bularni Ondiki kaⱨin Potifiraⱨning ⱪizi Asinat uningƣa tuƣup bǝrdi.
21 Àwọn ọmọ Benjamini: Bela, Bekeri, Aṣbeli, Gera, Naamani, Ehi, Roṣi, Mupimu, Huppimu àti Ardi.
Binyaminning oƣulliri: — Belaⱨ, Bǝkǝr, Axbǝl, Gera, Naaman, Eⱨi, Rox, Muppim, Ⱨuppim wǝ Ard.
22 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin tí Rakeli bí fún Jakọbu. Wọ́n jẹ́ mẹ́rìnlá lápapọ̀.
Bular Raⱨilǝning Yaⱪupⱪa tuƣup bǝrgǝn oƣul-ǝwladliri bolup, jǝmiy on tɵt jan idi.
23 Àwọn ọmọ Dani: Huṣimu.
Danning oƣli: — Ⱨuxim.
24 Àwọn ọmọ Naftali: Jasieli, Guni, Jeseri, àti Ṣillemu.
Naftalining oƣulliri: — Yaⱨziǝl, Guni, Yǝzǝr wǝ Xillǝm.
25 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ tí Biliha ẹni tí Labani fi fún Rakeli ọmọ rẹ̀ bí fún Jakọbu. Wọ́n jẹ́ méje lápapọ̀.
Bular Laban ⱪizi Raⱨilǝgǝ dedǝk boluxⱪa bǝrgǝn Bilⱨaⱨning Yaⱪupⱪa tuƣup bǝrgǝn oƣul-ǝwladliri bolup, jǝmiy yǝttǝ jan idi.
26 Gbogbo àwọn tí ó lọ pẹ̀lú Jakọbu sí Ejibiti, àwọn tí ó jẹ́ ìran rẹ̀ tààrà láìka àwọn aya ọmọ rẹ̀, jẹ́ ènìyàn mẹ́rìndínláàádọ́rin.
Yaⱪupning kelinliridin baxⱪa, Yaⱪupning puxtidin bolƣan, uning bilǝn birgǝ Misirƣa kǝlgǝnlǝr jǝmiy atmix altǝ jan idi.
27 Pẹ̀lú àwọn ọmọkùnrin méjì tí a bí fún Josẹfu ní Ejibiti àwọn ará ilé Jakọbu tí ó lọ sí Ejibiti jẹ́ àádọ́rin lápapọ̀.
Yüsüpning Misirda tuƣulƣan oƣulliri ikki idi. Yaⱪupning jǝmǝtidin bolup, Misirƣa kǝlgǝnlǝr jǝmiy yǝtmix jan idi.
28 Jakọbu sì rán Juda ṣáájú rẹ̀ lọ sọ́dọ̀ Josẹfu, kí wọn bá à le mọ ọ̀nà Goṣeni. Nígbà tí wọ́n dé agbègbè Goṣeni,
Yaⱪup Yüsüptin kɵrsǝtmǝ elip, ɵzlirini Goxǝngǝ baxlap berixⱪa Yǝⱨudani Yüsüpning ⱪexiƣa ǝwǝtti. Xundaⱪ ⱪilip ular Goxǝn yurtiƣa kelip qüxti.
29 Josẹfu tọ́jú kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀ ó sì lọ sí Goṣeni láti pàdé Israẹli baba rẹ̀. Bí Josẹfu ti dé iwájú baba rẹ̀, ó dì mọ́ baba rẹ̀ ó sì sọkún fún ìgbà pípẹ́.
Yüsüp ɵzining wǝzirlik ⱨarwisini ⱪatⱪuzup, atisi Israilning aldiƣa Goxǝngǝ qiⱪti. U ɵzini uning aldiƣa ⱨazir ⱪilip atisiƣa ɵzini etip boyniƣa girǝ selip ⱪuqaⱪlap, uzundin uzun yiƣlidi.
30 Israẹli wí fún Josẹfu pé, “Wàyí o, mo le kú, níwọ̀n bí mo ti rí i fún ara mi pé, o wà láààyè síbẹ̀.”
Israil Yüsüpkǝ: Mǝn sening yüzüngni kɵrüp, tirik ikǝnlikingni bildim; ǝmdi ɵlsǝmmu arminim yoⱪ, — dedi.
31 Nígbà náà ni Josẹfu wí fún àwọn arákùnrin rẹ̀ àti fún àwọn ará ilé baba rẹ̀ pé, “Èmi yóò gòkè lọ, èmi yóò sì bá Farao sọ̀rọ̀, èmi yóò sì wí fún un pé, ‘Àwọn arákùnrin mi àti ìdílé baba mi tí ń gbé ní Kenaani ti tọ̀ mí wá.
Andin Yüsüp ⱪerindaxliri wǝ atisining ɵydikilirigǝ mundaⱪ dedi: — Mǝn ⱨazir qiⱪip Pirǝwngǝ hǝwǝr berip: «Ⱪanaan zeminida olturƣan ⱪerindaxlirim, xundaⱪla atamning ɵyidikilǝr ⱪeximƣa kǝldi;
32 Darandaran ni àwọn ènìyàn náà, wọ́n ń tọ́jú ẹran ọ̀sìn, wọ́n sì kó agbo ẹran wọn àti agbo màlúù wọn àti gbogbo ohun tí wọ́n ní pẹ̀lú wá.’
bu adǝmlǝr padiqilar bolup, mal beⱪix bilǝn xuƣullinip kǝlgǝn, ⱪoy-kaliliri, xundaⱪla barliⱪ mal-mülüklirini elip kǝldi» dǝp eytay.
33 Nígbà tí Farao bá pè yín wọlé tí ó sí béèrè irú iṣẹ́ tí ẹ ń ṣe,
Xundaⱪ boliduki, Pirǝwn silǝrni qaⱪiridu; xu qaƣda u silǝrdin: «Nemǝ oⱪitinglar bar?» dǝp sorisa,
34 ẹ fún un lésì pé, ‘Àwọn ìránṣẹ́ rẹ ń tọ́jú ẹran ọ̀sìn ni láti ìgbà èwe wa wá gẹ́gẹ́ bí a ṣe ba a lọ́wọ́ àwọn baba wa.’ Nígbà náà ni wọn yóò fún un yín láààyè láti tẹ̀dó sí ilẹ̀ Goṣeni, nítorí pé àwọn ará Ejibiti kórìíra ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ darandaran.”
silǝr jawab berip: — Kǝminiliri kiqikimizdin tartip ata-bowilirimizƣa ohxax pada beⱪip kǝlgǝnmiz, — dǝnglar. Xundaⱪ desǝnglar Goxǝn yurtida olturup ⱪalisilǝr; qünki padiqilarning ⱨǝmmisi misirliⱪlar arisida kɵzgǝ ilinmaydu.