< Genesis 45 >
1 Josẹfu kò sì le è pa á mọ́ra mọ́ níwájú gbogbo àwọn tí ó dúró tì í. Ó sì sọkún sókè tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn tí ó wà ní àyíká gbọ́ ohun ẹkún rẹ̀. “Jẹ́ kí gbogbo ènìyàn kúrò ní ọ̀dọ̀ mi.” Kò sì sí ẹnikẹ́ni lọ́dọ̀ rẹ̀ nígbà tí ó fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀.
Joseph long khaw amah taengkah aka pai boeih taengah thiim uh ham a coeng voelpawt vaengah, “Hlang boeih loh kai taeng lamkah nong uh,” tila pang. Te dongah a taengkah hlang tloe aka pai te a om pawt vaengah Joseph loh a manuca rhoek taengah amah kawng te a phoe.
2 Ó sì sọkún sókè kíkankíkan tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn Ejibiti gbọ́ ohùn ẹkún rẹ̀, àwọn ilé Farao pẹ̀lú sì gbọ́ nípa rẹ̀.
Te vaengah rhahnah neh a ol a huel. Te dongah Egypt rhoek loh a yaak uh tih Pharaoh im long khaw a yaak.
3 Josẹfu wí fún àwọn arákùnrin rẹ̀ pé, “Èmi ni Josẹfu! Ṣe baba mi sì wà láààyè?” Ṣùgbọ́n àwọn arákùnrin rẹ̀ kò le è dá a lóhùn nítorí ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi, ẹnu sì yà wọ́n níwájú rẹ̀.
Te vaengah Joseph loh a manuca rhoek la, “Kai he Joseph ni. A pa hing pueng a?,” a ti nah. Tedae anih hmuh ah a manuca rhoek te let uh tih doo uh thai pawh.
4 Nígbà náà ni Josẹfu wí fún àwọn arákùnrin rẹ̀ pé, “Ẹ súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi.” Nígbà tí wọ́n sì ti ṣe bẹ́ẹ̀, ó wí pé, “Èmi ni Josẹfu arákùnrin yín tí ẹ tà sí ilẹ̀ Ejibiti!
Te vaengah Joseph loh a manuca rhoek la, “Kai taengla bet ha thoeih uh lah,” a ti nah tih a thoeih uh hatah, “Kai Joseph he na manuca ni. Kai he Egypt la nan yoih uh.
5 Ṣùgbọ́n báyìí, ẹ má ṣe banújẹ́, ẹ má sì ṣe bínú sí ara yín ní títà tí ẹ tà mí sí ìhín, nítorí, ọ̀nà àti gba ẹ̀mí yín là ni Ọlọ́run ṣe rán mi sí ìhín ṣáájú yín.
Tedae hinglu hlawtnah ham Pathen loh nangmih hmai ah kai n'tueih coeng dongah kai nan yoih uh te namamih kah mik dongah na ngaihlih sak uh boel lamtah sai boeh.
6 Ìyàn tí ó ti mú láti ọdún méjì sẹ́yìn yìí yóò tẹ̀síwájú fún ọdún márùn-ún sí i nínú èyí tí ẹnikẹ́ni kò ní gbìn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ni kórè.
Tahae lamkah khokha kum loh kho khui ah om vetih kum nga ngawn tah lotawn cangah mueh la om pueng ni.
7 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run rán mi ṣáájú yín sí ìhín láti da irú-ọmọ yín sí fún un yín lórí ilẹ̀ ayé àti láti fi ìgbàlà ńlá gba ẹ̀mí yín là.
Tedae diklai ah a meet la nangmih te n'hoep phoeiah loeihnah tanglue neh nangmih te hing sak ham ni nangmih hmai ah Pathen loh kai n'tueih.
8 “Nítorí náà, kì í ṣe ẹ̀yin ni ó rán mi wá sí ibí yìí, bí kò ṣe Ọlọ́run. Ó fi mí ṣe baba, Olùdámọ̀ràn fún Farao, olúwa fún gbogbo ilé Farao àti alákòóso gbogbo ilẹ̀ Ejibiti.
Te dongah nangmih loh hela kai nan tueih uh moenih. Tedae Pathen loh kai he Pharaoh napa lam khaw, amah im pum kah boei lam khaw, Egypt kho tom aka taemrhai ham khaw, n'khueh.
9 Nísinsin yìí, ẹ yára padà sọ́dọ̀ baba mi kí ẹ sì wí fun un pé, èyí ni ohun tí Josẹfu ọmọ rẹ wí, Ọlọ́run ti fi mí ṣe olúwa fún gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, ẹ sọ̀kalẹ̀ wá láì jáfara.
A pa taengah a loe la cet uh lamtah, 'Na capa Joseph te Pathen loh Egypt pum kah boei la a khueh coeng,'. Uelh mueh la kai taengah na suntla uh tih,
10 Ìwọ yóò gbé ní agbègbè Goṣeni, ìwọ kì yóò jìnnà sí mi, àwọn ọmọ rẹ àti àwọn ọmọ ọmọ rẹ, àwọn agbo ẹran rẹ àti agbo màlúù rẹ àti gbogbo ohun tí ìwọ ní.
kamah neh a yoei la om ham Goshen kho ah a pa namah khaw, na ca rhoek khaw, na ca rhoek kah a ca rhoek patoeng khaw, na boiva khaw, na saelhung neh na taengkah aka om boeih te khaw kho na sak uh bitni.
11 Èmi yóò pèsè fún yín níbẹ̀. Nítorí ó ṣì ku ọdún márùn-ún gbáko ti ìyàn yóò fi mú. Kí ìwọ àti ilé rẹ àti ohun tí í ṣe tìrẹ má ba à di aláìní.
Khokha he kum nga a om pueng dongah nangmih te kan cangbam bitni. Namah khaw, na im khaw na taengkah aka om boeih khaw tal ve,’ a ti,’ ti nah.
12 “Ẹ̀yin fúnra yín àti Benjamini arákùnrin mi pẹ̀lú rí i pé, lóòótọ́ lóòótọ́, èmi Josẹfu ni mo ń bá a yín sọ̀rọ̀.
Tahae ah kamah ka neh nangmih taengah ka thui he nangmih mik neh ka mana Benjamin mik loh rhep a hmuh he.
13 Ẹ sọ fún baba mi nípa gbogbo ọlá tí a fún mi ní ilẹ̀ Ejibiti àti ohun gbogbo tí ẹ̀yin ti rí, kí ẹ sì mú baba mi tọ̀ mí wá sí ìhín yìí kíákíá.”
Egypt ah kai, thangpomnah cungkuem neh nan hmuh uh boeih te a pa taengah puen uh lamtah a pa te pahoi tlek han khuen uh,” a ti nah.
14 Nígbà náà ni ó dì mọ́ Benjamini arákùnrin rẹ̀, ó sì sọkún, Benjamini náà sì dì mọ́ ọn, pẹ̀lú omijé lójú.
Te phoeiah a mana Benjamin te a rhawn ah a kop tih rhap. Benjamin long khaw a rhawn ah a kop tih rhap van.
15 Ó sì tún fẹnu ko gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ lẹ́nu, ó sì sọkún sí wọn lára. Lẹ́yìn èyí, Josẹfu àti àwọn arákùnrin rẹ̀ sọ̀rọ̀ pọ̀.
A manuca rhoek te rhip a mok tih a rhah thil. Te phoei daengah a manuca rhoek loh anih taengah cal uh.
16 Nígbà tí ìròyìn náà dé ààfin Farao pé àwọn arákùnrin Josẹfu dé, inú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀ dùn.
Tedae Joseph kah a manuca rhoek halo uh a ti te Pharaoh im loh olthang a yaak vaengah Pharaoh mik ah khaw, a sal rhoek mik ah khaw cop.
17 Farao wí fún Josẹfu pé, “Wí fún àwọn arákùnrin rẹ pé, ‘Èyí ni kí ẹ ṣe, ẹ di ẹrù lé ẹranko yín kí ẹ sì padà sí ilẹ̀ Kenaani,
Te dongah Pharaoh loh Joseph taengah, “He tlam he saii mai. Na manuca rhoek la, 'Na rhamsa neh sawn uh lamtah Kanaan kho la bal uh ngawn.
18 kí ẹ sì mú baba yín àti ìdílé yín tọ̀ mí wá. Èmi yóò fún un yín ní ibi tí ó dára jùlọ ní ilẹ̀ Ejibiti, ẹ̀yin yóò sì le è gbádùn ilẹ̀ yìí.’
Na pa te khaw, na imkhui khaw, lo uh lamtah kai taengla han khuen uh. Nangmih te Egypt khohmuen kah a thennah kam paek vetih lai men te na caak uh bitni.
19 “A pàṣẹ fún ọ láti sọ fún wọn pé, ‘Ẹ ṣe èyí. ẹ mú kẹ̀kẹ́ ẹrù láti ilẹ̀ Ejibiti fún àwọn ọmọ yín àti àwọn aya yín. Kí ẹ sì mú baba yín tọ mí wá.
Te phoeiah namah loh uen lamtah saii. Na ca rhoek ham khaw, na yuu rhoek ham khaw, na pa te khaw lo uh. Te phoeiah na bal uh vaengkah ham leng te Egypt kho lamloh namah neh puei uh.
20 Ẹ má ṣe àníyàn nípa ohun ìní yín nítorí èyí tí ó dára jù nínú ilẹ̀ Ejibiti yóò jẹ́ tiyín.’”
Egypt khohmuen kah a thennah boeih he nangmih ham coeng dongah na hnopai khaw na mik dongah rhen boeh,’ ti nah,” a ti nah.
21 Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe èyí. Josẹfu fún wọn ni kẹ̀kẹ́ ẹrù bí Farao ti pàṣẹ, ó sì fún wọn ní oúnjẹ fún ìrìnàjò wọn pẹ̀lú.
Te dongah Isreal ca rhoek loh a saii uh tih Pharaoh kah olpaek vanbangla amih te Joseph loh leng a paek. Te phoeiah amih te longpueng ham lampu khaw a paek.
22 Ó fún ẹni kọ̀ọ̀kan wọn ní aṣọ tuntun. Ṣùgbọ́n Benjamini ni ó fún ní ọ̀ọ́dúnrún ẹyọ owó idẹ fàdákà àti ìpààrọ̀ aṣọ márùn-ún.
Amih ham thovaelnah himbai te khat khat rhip a paek tih Benjamin te tah tangka ya thum neh himbai thovaelnah ham yung nga a paek.
23 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ó kó ránṣẹ́ sí baba rẹ̀: kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá tí ó ru àwọn ohun mèremère ilẹ̀ Ejibiti àti abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá tí ó ru ọkà àti oríṣìíríṣìí oúnjẹ.
A napa ham khaw Egypt kah a thennah aka phuei laak pumrha, cang, caak neh a napa ham longpueng kah lampu aka phuei laaknu pumrha te a pat pah.
24 Nígbà náà ni ó rán àwọn arákùnrin rẹ̀ lọ, bí wọ́n ṣe ń pínyà, ó wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe jà ní ọ̀nà o!”
Tedae a manuca rhoek te a tueih tih a hlah uh vaengah amih te, “Longpueng ah tlai uh boeh ne,” a ti nah.
25 Báyìí ni wọ́n jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti wá sí ọ̀dọ̀ Jakọbu baba wọn ní ilẹ̀ Kenaani.
Te phoeiah Egypt lamkah Kanaan kho la cet uh tih a napa Jakob te a paan uh.
26 Wọn wí fún un pé, “Josẹfu ṣì wà láààyè! Kódà òun ni alákòóso ilẹ̀ Ejibiti.” Ẹnu ya Jakọbu, kò sì gbà wọ́n gbọ́.
Te phoeiah Jakob taengah, “Joseph hing pueng tih anih loh Egypt kho boeih a taem a rhai,” tila a puen pauh. Tedae a lungbuei a lungmit coeng tih amih te tangnah pawh.
27 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n sọ ohun gbogbo tí Josẹfu ti sọ fún wọn fún un tí ó sì rí kẹ̀kẹ́ ẹrù tí Josẹfu fi ránṣẹ́ láti gbé e padà wá, iyè Jakọbu, baba wọn sọ.
Tedae Joseph loh amih taengah a thui olka boeih te Jakob taengah a thui pa uh tih amah aka phuei ham Joseph kah a pat leng te a hmuh vaengah a napa Jakob kah a mueihla koep hing.
28 Israẹli sì wí pé, “Mo gbà dájúdájú wí pé, Josẹfu ọmọ mi wà láààyè. Èmi ó lọ rí i kí n tó kú.”
Te daengah Israel loh, “Rhoek saeh, ka ca Joseph a hing pueng te ka duek hlanah ka cet vetih a muei ka hmu dae ni,” a ti.