< Genesis 42 >

1 Nígbà tí Jakọbu mọ̀ pé ọkà wà ní Ejibiti, ó wí fún àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin pé, “Èéṣe tí ẹ ń wo ara yín lásán?”
A IKE ae la o Iakoba, he ai ma Aigupita, olelo aku la o Iakoba i kana poe keikikane, O ke aha ka oukou e nana aku nei, kekahi i kekahi?
2 “Mo tí gbọ́ pé ọkà wà ní ilẹ̀ Ejibiti. Ẹ sọ̀kalẹ̀ lọ sí ibẹ̀ kí ẹ sì rà wá fún wa, kí a má ba à kú.”
Olelo aku la ia, Aia hoi, ua lohe au, ho ai ma Aigupita, E iho aku oukou ilaila, e kuai i ai na kakou, i ola kakou, aole e make.
3 Nígbà náà ni mẹ́wàá nínú àwọn arákùnrin Josẹfu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti láti ra ọkà.
Hele aku la ka poe kaikuaana o Iosepa he umi ilalo i Aigupita e kuai i ai.
4 Ṣùgbọ́n Jakọbu kò rán Benjamini àbúrò Josẹfu lọ pẹ̀lú wọn nítorí ẹ̀rù ń bà á kí aburú má ba à ṣẹlẹ̀ sí i.
A o Beniamina, ke kaikaina o Iosepa, aole o Iakoba i hoouna aku ia ia me kona poe kaikunana, no ka mea, i olelo iho la ia, O poino kela.
5 Nítorí náà, àwọn ọmọ Israẹli wà lára àwọn tó lọ Ejibiti lọ ra oúnjẹ nítorí ìyàn náà mú ni ilẹ̀ Kenaani pẹ̀lú.
Hele pu ae la na keiki a Iseraela iwaena o ka poe hele, e kuai i ai, no ka mea, ua wi loa ka aina o Kanaana.
6 Nísinsin yìí, Josẹfu ni alábojútó fún gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, òun sì ni ó ń bojútó ọkà títà fún gbogbo ènìyàn ìlú náà. Nítorí náà nígbà tí àwọn arákùnrin Josẹfu dé, wọ́n tẹríba, wọ́n sì foríbalẹ̀ fún Josẹfu.
O Iosepa no ke kiaaina olaila, a nana no i kuai na na kanaka a pau o ia aina. Hele mai la ka poe kaikuaana o Iosepa, a kulou iho la lakou imua ona, me na maka i ka honua.
7 Lọ́gán tí Josẹfu ti rí àwọn arákùnrin rẹ̀ ni ó ti dá wọn mọ̀, ṣùgbọ́n ó ṣe bí i wí pé kò mọ̀ wọ́n, ó sì sọ̀rọ̀ líle sí wọn. Ó béèrè pé, “Níbo ni ẹ ti wá?” Wọ́n sì dáhùn pé, “Láti ilẹ̀ Kenaani ni a ti wá ra oúnjẹ.”
A nana aku la o Iosepa i kona poe kaikuaana, ike ae la oia ia lakou, a hoohuahualau aku oia ia lakou, olelo koikoi aku la oia ia lakou, i aku la ia lakou, Nohea mai oukou? Olelo mai la lakou, No ka aina o Kanaana mai, e kuai i ai.
8 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, Josẹfu mọ àwọn arákùnrin rẹ̀, síbẹ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀ kò mọ̀ ọ́n.
Ua ike no o Iosepa i kona poe kaikuaana, aole nae lakou i ike ia ia.
9 Nígbà náà ni ó rántí àlá rẹ̀ tí ó lá sí wọn, ó sì wí fún wọn pé, “Amí ni yín, ẹ wá láti wo àṣírí ilẹ̀ wa ni.”
Hoomanao iho la o Iosepa i na moe ana i moe ai no lakou, i aku la oia ia lakou, He poe kiu oukou; ua hele mai oukou e nana i ka hemahema o ka aina.
10 Wọ́n dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́ olúwa wa, àwọn ìránṣẹ́ rẹ wá láti ra oúnjẹ ni.
Olelo mai la lakou ia ia, Aole ia, e kuu haku. I hele mai kau poe kauwa e kuai i ai.
11 Ọmọ baba ni wá, olóòtítọ́ ènìyàn sì ni wá pẹ̀lú, àwa kì í ṣe ayọ́lẹ̀wò.”
He poe keiki makou a pau na ke kanaka hookahi; he poe kanaka pono, aole he poe kin makou o kau poe kauwa.
12 Ó wí fún wọn pé, “Rárá! Ẹ wá láti wo àṣírí ilẹ̀ wa ni.”
Olelo aku la ia ia lakou, Aole, ua hele mai nei oukou e nana i ka hemahema o ka aina.
13 Ṣùgbọ́n wọ́n tún dáhùn pé, “Arákùnrin méjìlá ni àwa ìránṣẹ́ rẹ, ọmọ baba kan náà, tí ó ń gbé ní ilẹ̀ Kenaani. Èyí tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn wa ń bẹ lọ́dọ̀ baba wa, ọ̀kan sì ti kú.”
Olelo mai la lakou, O kau poe kauwa, he umi makou a me kumamalua o ko makou hanauna, na keiki a ke kanaka hookahi i ka aina o Kanaana, aia hoi ka muli loa i keia la me ka makuakane o makou, a o kekahi hoi, aole ia.
14 Josẹfu wí fún wọn pé, “Bí mo ti wí fún un yín náà ni, Ayọ́lẹ̀wò ni yín!
Olelo aku la o Iosepa ia lakou, Oia hoi ka'u i olelo aku nei ia oukou, he poe kiu oukou.
15 Èyí sì ni a ó fi dán an yín wò, èmi búra pé, níwọ̀n ìgbà tí Farao bá wà láààyè, ẹ kì yóò kúrò níbí, àyàfi bí arákùnrin yín kan tókù bá wá sí ibí.
I keia mea e ikea ai oukou, ma ke ola o Parao, aole oukou e hoi aku, ke hiki ole mai ko oukou kaikaina.
16 Ẹ rán ọ̀kan nínú yín lọ láti mú arákùnrin yín wá, àwa yóò fi ẹ̀yin tókù pamọ́ sínú túbú, kí àwa ba à lè mọ bóyá òtítọ́ ni ẹ̀yin ń wí. Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé irọ́ ni ẹ̀yin ń pa, ní òtítọ́ bí Farao ti ń bẹ láààyè ayọ́lẹ̀wò ni yín!”
E hoouna ae i kekahi o oukou e kii i ko oukou kaikaina, a e paa oukou, i ikea ka oukou olelo a me ka pono io o oukou, aka, i ole, ma ke ola o Parao, he poe kiu io no oukou.
17 Ó sì fi gbogbo wọn sínú túbú fún ọjọ́ mẹ́ta.
A hoakoakoa mai la oia ia lakou a pau iloko o kahi paa, a ekolu la.
18 Ní ọjọ́ kẹta, Josẹfu wí fún wọn pé, “Èyí ni ẹ̀yin yóò ṣe kí ẹ̀yin ba à le yè nítorí mo bẹ̀rù Ọlọ́run.
A i ka po akolu, olelo aku la o Iosepa ia lakou, E hana oukou i keia, i ola oukou; ua makau wau i ke Akua.
19 Tí ó bá jẹ́ pé olóòtítọ́ ènìyàn ni yín, ẹ jẹ́ kí ọ̀kan nínú yín dúró ni túbú ní ìhín, nígbà tí àwọn yòókù yín yóò gbé ọkà lọ fún àwọn ará ilé e yín tí ebi ń pa.
Ina he poe kanaka pono oukou, e paaia kekahi o oukou i ka halepaahao: e hoi aku oukou e halihali i ai na ka wi o ko oukou mau hale:
20 Ṣùgbọ́n ẹ gbọdọ̀ mú arákùnrin tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn yín wá, kí n ba à le mọ òtítọ́ ohun ti ẹ ń wí, kí ẹ má ba à kú.” Wọn sì gbà láti ṣe èyí.
A e lawe mai i ko oukou kaikaina io'u nei, pela e oiaio ai ka oukou olelo, alaila, aole oukou e make. Hana mai la lakou pela.
21 Wọ́n ń sọ ọ́ láàrín ara wọn wí pé, “Àwa jẹ̀bi nítòótọ́ nípa ti arákùnrin wa. A rí ìbànújẹ́ ọkàn rẹ̀ nígbà tí ó ń bẹ̀ wá nítorí ẹ̀mí rẹ̀, ṣùgbọ́n a kò gbẹ́bẹ̀, nítorí náà ni ìdààmú yìí fi dé bá wa.”
Olelo ae la lakou kekahi i kekahi, Ua hewa io kakou i ko kakou kaikaina, no ka mea, ua ike kakou i ka ehaeha o kona naau, i ka manawa ana i noi mai ai ia kakou, aole kakou i hoolohe aku; no ia mea, ua hiki mai keia popilikia io kakou nei.
22 Reubeni dá wọn ní ohùn pé, “Èmi kò wí fún yín pé kí ẹ má se ṣẹ̀ sí ọmọdékùnrin náà? Ṣùgbọ́n ẹ kò gbọ́! Ṣùgbọ́n nísinsin yìí a ń béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ wa.”
A olelo aku la o Reubena ia lakou, i aku la, Aole anei au i olelo aku ia oukou, i ka i ana aku, Mai hana hewa aku i ke keiki? Aole oukou i hoolohe mai. Aia hoi, no ia mea, ua imiia mai ko ia la koko.
23 Wọn kò sì mọ̀ pé, Josẹfu ń gbọ́ wọn ní àgbọ́yé nítorí ògbufọ̀ ni ó ń lò tẹ́lẹ̀.
Aole i ike lakou ua lohe pono o Iosepa ia lakou, no ka mea, ua olelo aku oia ia lakou, ma ke kanaka hoohalike olelo.
24 Ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún. Ó sì tún yí padà sí wọn, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ní sọ̀rọ̀. Ó mú Simeoni kúrò láàrín wọn, ó sì dè é ní ojú wọn.
Haliu aku la ia, mai o lakou la, a uwe iho la; haliu hou mai la oia ia lakou, kamailio pu me lakou, a lawe mai la oia ia Simeona, mai o lakou mai la, a hana paa iho la ia ia mamua o ko lakou mau maka.
25 Josẹfu pàṣẹ pé kí wọn bu ọkà kún inú àpò wọn, kí wọn sì mú owó ẹnìkọ̀ọ̀kan padà sínú àpò rẹ̀, kí wọn sì fún wọn ní ohun tí wọn yóò lò nírín-àjò wọn padà sílé. Lẹ́yìn ìgbà tí a ti ṣe èyí fún wọn,
Alaila, kauoha aku la o Iosepa, e uhao i ka ai i na eke a lakou a piha, a e hoihoi i ka moni a lakou iloko o ka lakou mau eke, a e haawi aku i o na lakou no ke alanui. Pela oia i hana aku ai ia lakou.
26 wọn gbé ẹrù wọn lé kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, wọn sì padà lọ sí ilé.
Hooili ae la lakou i ka ai iluna iho o ko lakou mau hoki, a hele aku la.
27 Níbi tí wọ́n ti dúró láti sùn lóru ọjọ́ náà, ọ̀kan nínú wọn tú àpò rẹ̀ láti mú oúnjẹ fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó sì rí owó rẹ̀ ní ẹnu àpò rẹ̀.
A i ka wehe ana o kekahi i kana eke, e haawi aku i ai na kona hoki, ma kahi oioina, ike ae la ia i kana moni, no ka mea, aia hoi ia ma ka waha o kana eke.
28 Ó sì wí fún àwọn arákùnrin rẹ̀ pé, “a ti dá owó mi padà, òun nìyí ní ẹnu àpò mi.” Ẹ̀rù bà wọ́n, wọ́n sì ń gbọ̀n, wọ́n sì wí pé, “Èwo nìyí tí Ọlọ́run ṣe sí wa yìí.”
A olelo aku la ia i kona poe hoahanau, E, ua hoihoiia mai ka'u moni; eia hoi ia iloko o ka'u eke. Hikilele iho la ko lakou naau, haalulu iho la lakou, i aku la kekahi i kekahi, Heaha keia mea a ke Akua i hana mai ai ia kakou?
29 Nígbà tí wọ́n padà dé ọ̀dọ̀ Jakọbu baba wọn ní ilẹ̀ Kenaani, wọ́n ròyìn gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún un wí pé,
A hiki lakou io Iakoba la, i ko lakou makuakane i ka aina o Kanaana, hai aku la lakou ia ia i na mea a pau i loaa'i ia lakou; i aku la,
30 “Ọkùnrin náà tí í ṣe alábojútó ilẹ̀ náà, sọ̀rọ̀ líle sí wa, ó sì fi ẹ̀sùn kàn wá pé a wá yọ́ ilẹ̀ náà wò ni.
O ke kanaka, ka haku o ka aina i olelo koikoi mai ai ia makou; ua kuhi mai kela ia makou, he poe kiu no ka aina.
31 Ṣùgbọ́n, a wí fún un pé, ‘Rárá o, olóòtítọ́ ènìyàn ni wá, a kì í ṣe ayọ́lẹ̀wò.
A olelo aku la makou ia ia, He poe pono makou; aohe makou he kiu.
32 Arákùnrin méjìlá ni wá, ọmọ baba kan náà, ọ̀kan ti kú, èyí tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn wà lọ́dọ̀ baba wa ni ilẹ̀ Kenaani.’
He poe hanauna makou, he umi a me kumamalua, na keiki a ko makou makuakane; aole kekahi, a o ka muli loa, aia no ia i keia la me ko makou makuakane, i ka aina o Kanaana.
33 “Nígbà náà ni ọkùnrin tí ó jẹ́ alábojútó ilẹ̀ náà wí fún wa pé, ‘Báyìí ni n ó ṣe mọ̀ bóyá olóòtítọ́ ènìyàn ni yín, ẹ fi ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin yín sílẹ̀ níbí, pẹ̀lú mi, ẹ sì mú oúnjẹ lọ fún àwọn ará ilé yín tí ebi ń pa kú lọ, lọ́wọ́ ìyàn.
A o ke kanaka, ka haku o ka aina, olelo mai la ia makou, I keia mea e ikeia'i he poe kanaka pono oukou, E waiho mai oukou i kekahi hoahanau o oukou me au, a e lawe i ai na ka wi o ko oukou mau hale, a e hoi aku:
34 Ṣùgbọ́n ẹ mú arákùnrin yín tí ó kéré jùlọ wá fún mi kí n le mọ̀ pé dájúdájú ẹ kì í ṣe ayọ́lẹ̀wò bí kò ṣe ènìyàn tòótọ́. Nígbà náà ni n ó mú arákùnrin yín padà fún un yín, lẹ́yìn náà ẹ le máa wá ṣe òwò bí ó ti wù yín ní ilẹ̀ yìí.’”
A e lawe mai oukou i ko oukou kaikaina io'u nei; alaila, ike au ia oukou, aohe kiu, he poe kanaka maikai no oukou; a e kuu aku au ia oukou i ko oukou hoahanau, a e kuai oukou iloko o keia aina.
35 Bí wọ́n sì ti ń tú àpò ẹrù wọn, ẹnìkọ̀ọ̀kan bá owó tí ó san fún ọjà náà lẹ́nu àpò rẹ̀! Ẹ̀rù sì bà wọ́n gidigidi, àwọn àti baba wọn.
A i ka ninini ana aku a lakou i ka lakou mau eke, aia hoi, iloko o na eke a lakou, ka lakou mau laulau moni a pau. A ike ae la lakou a me ko lakou makuakane i na laulau moni, makau nui iho la lakou.
36 Jakọbu baba wọn wí fún wọn pé, “Ẹ ti mú mi pàdánù àwọn ọmọ mi. N kò rí Josẹfu mọ́, bẹ́ẹ̀ ni n kò sì rí Simeoni náà mọ. Ẹ sì tún fẹ́ mú Benjamini lọ. Èmi ni gbogbo ohun búburú yìí wá ń ṣẹlẹ̀ sí!”
A olelo mai la o Iakoba ko lakou makuakane ia lakou, Ua hoonele mai oukou ia'u i ka'u mau keiki. O Iosepa, aole ia, a o Simeona, aole ia, a e lawe aku ana oukou ia Beniamina. Ke pale mai nei keia mau mea a pau ia'u.
37 Nígbà náà ni Reubeni wí fún baba rẹ̀ pé, “Pa àwọn ọmọ mi méjèèjì bí n kò bá mú Benjamini padà wá fún ọ, èmi ni kí o fà á lé lọ́wọ́, n ó sì mu un padà wá.”
Olelo aku la o Reubena i kona makuakane, i aku la, E pepehi mai oe i ka'u mau keiki elua, ke hoihoi ole mai au ia ia nei iou la; e haawi mai oe ia ia nei i kuu lima, na'u ia e hoihoi hou mai iou la.
38 Ṣùgbọ́n Jakọbu wí pé, “Ọmọ mi kì yóò bá a yín lọ, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ti kú, òun nìkan sì ni ó kù nínú àwọn ọmọ ìyá rẹ̀. Bí ohunkóhun bá ṣẹlẹ̀ sí i, ìbànújẹ́ ni yóò sì pa mi kú ni ọjọ́ ogbó mi yìí.” (Sheol h7585)
Olelo mai la ia, Aole e iho aku ka'u keiki me oukou ilaila, no ka mea, ua make kona kaikuaana, oia nei wale no koe: ina poino keia, ma ke alanui a oukou e hele ai, alaila, lawe iho oukou i ko'u oho hina i ka lua me ke kaniuhu. (Sheol h7585)

< Genesis 42 >