< Genesis 42 >

1 Nígbà tí Jakọbu mọ̀ pé ọkà wà ní Ejibiti, ó wí fún àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin pé, “Èéṣe tí ẹ ń wo ara yín lásán?”
Kane Jakobo owinjo ni cham yudore e piny Misri, nowacho ne yawuote niya, “Angʼo ma omiyo ubet urangoru aranga?”
2 “Mo tí gbọ́ pé ọkà wà ní ilẹ̀ Ejibiti. Ẹ sọ̀kalẹ̀ lọ sí ibẹ̀ kí ẹ sì rà wá fún wa, kí a má ba à kú.”
Nodhi nyime kowachonegi niya, “asewinjo ni nitie cham e piny Misri. Dhiuru kuno kendo ungʼiewnwa cham, mondo mi wabed mangima kendo kech kik negwa.”
3 Nígbà náà ni mẹ́wàá nínú àwọn arákùnrin Josẹfu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti láti ra ọkà.
Eka owete Josef apar nodhi Misri mondo odhi ongʼiew cham.
4 Ṣùgbọ́n Jakọbu kò rán Benjamini àbúrò Josẹfu lọ pẹ̀lú wọn nítorí ẹ̀rù ń bà á kí aburú má ba à ṣẹlẹ̀ sí i.
To Jakobo ne ok ooro Benjamin mowadgi Josef hie kodgi nikech noluor ni dipo ka gimoro ohinye.
5 Nítorí náà, àwọn ọmọ Israẹli wà lára àwọn tó lọ Ejibiti lọ ra oúnjẹ nítorí ìyàn náà mú ni ilẹ̀ Kenaani pẹ̀lú.
Kuom mano yawuot Jakobo kaachiel gi jo-Kanaan nodhi ngʼiewo cham nikech kech momako pinygi.
6 Nísinsin yìí, Josẹfu ni alábojútó fún gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, òun sì ni ó ń bojútó ọkà títà fún gbogbo ènìyàn ìlú náà. Nítorí náà nígbà tí àwọn arákùnrin Josẹfu dé, wọ́n tẹríba, wọ́n sì foríbalẹ̀ fún Josẹfu.
To Josef ma jatend pinyno ema ji moa e pinje duto ne biro rundo kuome. Kuom mano, kane owete Josef ochopo, negikulore ne Josef nyaka e lowo.
7 Lọ́gán tí Josẹfu ti rí àwọn arákùnrin rẹ̀ ni ó ti dá wọn mọ̀, ṣùgbọ́n ó ṣe bí i wí pé kò mọ̀ wọ́n, ó sì sọ̀rọ̀ líle sí wọn. Ó béèrè pé, “Níbo ni ẹ ti wá?” Wọ́n sì dáhùn pé, “Láti ilẹ̀ Kenaani ni a ti wá ra oúnjẹ.”
Kane Josef oneno owetene, nofwenyogi to nowuondore mondo kik gingʼeye. Kendo nowuoyo kodgi gi gero kopenjogi niya, “Ua kanye?” To negidwoke niya, “Waa e piny Kanaan mondo wabi warund chiemo.”
8 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, Josẹfu mọ àwọn arákùnrin rẹ̀, síbẹ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀ kò mọ̀ ọ́n.
Kata obedo ni Josef nofwenyo owetene, gin to ne ok gifwenye.
9 Nígbà náà ni ó rántí àlá rẹ̀ tí ó lá sí wọn, ó sì wí fún wọn pé, “Amí ni yín, ẹ wá láti wo àṣírí ilẹ̀ wa ni.”
Eka noparo lek mane oleko kuomgi kendo nowachonegi niya, “Un okwach kich! Kendo usebiro mondo une-ane kama pinywa nyapgodo.”
10 Wọ́n dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́ olúwa wa, àwọn ìránṣẹ́ rẹ wá láti ra oúnjẹ ni.
To negidwoke niya, “Ooyo ruodha. Jotichgi obiro mana mondo orund chiemo.
11 Ọmọ baba ni wá, olóòtítọ́ ènìyàn sì ni wá pẹ̀lú, àwa kì í ṣe ayọ́lẹ̀wò.”
Waduto wan yawuot ngʼat achiel. Jotichgi gin joma kare, ma ok okwach kich.”
12 Ó wí fún wọn pé, “Rárá! Ẹ wá láti wo àṣírí ilẹ̀ wa ni.”
To Josef nomedo wachonegi niya, “Ooyo! Usebiro mana ni mondo ungʼe kama pinywa nyapgodo.”
13 Ṣùgbọ́n wọ́n tún dáhùn pé, “Arákùnrin méjìlá ni àwa ìránṣẹ́ rẹ, ọmọ baba kan náà, tí ó ń gbé ní ilẹ̀ Kenaani. Èyí tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn wa ń bẹ lọ́dọ̀ baba wa, ọ̀kan sì ti kú.”
To negiwacho niya, “Ruoth, jotichni ne yawuowi apar gariyo, yawuot ngʼat achiel, wadak e piny Kanaan. Owadwa ma chogo nyo odongʼ gi wuonwa, to achiel to ne olal.”
14 Josẹfu wí fún wọn pé, “Bí mo ti wí fún un yín náà ni, Ayọ́lẹ̀wò ni yín!
Josef nowachonegi niya, “En mana kaka ne awachonu: Un okwach kich!
15 Èyí sì ni a ó fi dán an yín wò, èmi búra pé, níwọ̀n ìgbà tí Farao bá wà láààyè, ẹ kì yóò kúrò níbí, àyàfi bí arákùnrin yín kan tókù bá wá sí ibí.
Kendo ma e kaka ibiro temu: Akwongʼora e nying Farao ni ok unuwuok ka makmana ka ukelo owadu ma chogo ka.
16 Ẹ rán ọ̀kan nínú yín lọ láti mú arákùnrin yín wá, àwa yóò fi ẹ̀yin tókù pamọ́ sínú túbú, kí àwa ba à lè mọ bóyá òtítọ́ ni ẹ̀yin ń wí. Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé irọ́ ni ẹ̀yin ń pa, ní òtítọ́ bí Farao ti ń bẹ láààyè ayọ́lẹ̀wò ni yín!”
Oruru achiel kuom oweteu mondo odhi oom owadu; to joma odongʼ ibiro kano e od twech, mondo mi wane anena ka weche ma uwacho gin adier. To ka ok gin adier, to akwongʼora gi nying Farao, ni un okwach kich!”
17 Ó sì fi gbogbo wọn sínú túbú fún ọjọ́ mẹ́ta.
Kendo noketogi duto e od twech kuom ndalo adek.
18 Ní ọjọ́ kẹta, Josẹfu wí fún wọn pé, “Èyí ni ẹ̀yin yóò ṣe kí ẹ̀yin ba à le yè nítorí mo bẹ̀rù Ọlọ́run.
Odiechiengʼ mar adek, Josef nowachonegi niya, “Timuru ma mondo mi udagi, nikech aluoro Nyasaye:
19 Tí ó bá jẹ́ pé olóòtítọ́ ènìyàn ni yín, ẹ jẹ́ kí ọ̀kan nínú yín dúró ni túbú ní ìhín, nígbà tí àwọn yòókù yín yóò gbé ọkà lọ fún àwọn ará ilé e yín tí ebi ń pa.
Ka un joma kare, weuru achiel kuomu odongʼ ka, to joma odongʼ to odhiyo kendo oter cham ne joodu makoro chandore ka.
20 Ṣùgbọ́n ẹ gbọdọ̀ mú arákùnrin tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn yín wá, kí n ba à le mọ òtítọ́ ohun ti ẹ ń wí, kí ẹ má ba à kú.” Wọn sì gbà láti ṣe èyí.
To nyaka ukel owadu ma chogo ira, mondo omi angʼe ni uwacho adieri kendo mondo owaduni kik tho.” Kendo negitimo kamano.
21 Wọ́n ń sọ ọ́ láàrín ara wọn wí pé, “Àwa jẹ̀bi nítòótọ́ nípa ti arákùnrin wa. A rí ìbànújẹ́ ọkàn rẹ̀ nígbà tí ó ń bẹ̀ wá nítorí ẹ̀mí rẹ̀, ṣùgbọ́n a kò gbẹ́bẹ̀, nítorí náà ni ìdààmú yìí fi dé bá wa.”
Negiwacho e kindgi giwegi niya, “Adier kum ni waseyudo nikech owadwa. Ne waneno ka chunye chandore kane osayowa mondo wares ngimane to ne ok wanyal winje. Ma ema omiyo chandruogni osebironwa.”
22 Reubeni dá wọn ní ohùn pé, “Èmi kò wí fún yín pé kí ẹ má se ṣẹ̀ sí ọmọdékùnrin náà? Ṣùgbọ́n ẹ kò gbọ́! Ṣùgbọ́n nísinsin yìí a ń béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ wa.”
Reuben nodwokogi niya, “Donge ne akwerou ni kik utimne rawerano marach? To ne ok unyal winja! Koro nyaka chulnwa kuor nikech rembe.”
23 Wọn kò sì mọ̀ pé, Josẹfu ń gbọ́ wọn ní àgbọ́yé nítorí ògbufọ̀ ni ó ń lò tẹ́lẹ̀.
To ne ok gingʼeyo ni Josef owinjo gima giwacho nikech Josef noketo ngʼama lokone wach.
24 Ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún. Ó sì tún yí padà sí wọn, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ní sọ̀rọ̀. Ó mú Simeoni kúrò láàrín wọn, ó sì dè é ní ojú wọn.
Kane Josef owuok irgi, noywak ahinya, bangʼe noduogo irgi mochako wuoyo kodgi. Nokawo Simeon mi otweye e nyimgi ka gineno.
25 Josẹfu pàṣẹ pé kí wọn bu ọkà kún inú àpò wọn, kí wọn sì mú owó ẹnìkọ̀ọ̀kan padà sínú àpò rẹ̀, kí wọn sì fún wọn ní ohun tí wọn yóò lò nírín-àjò wọn padà sílé. Lẹ́yìn ìgbà tí a ti ṣe èyí fún wọn,
Josef nogolo chik mondo oket cham e ogundegi, odwokne ngʼato ka ngʼato pesane mane obirogo e ogunde, kendo mondo omigi gima ginyalo chamo e wangʼ yo ka gidok. Bangʼ kane osetimonegi ma,
26 wọn gbé ẹrù wọn lé kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, wọn sì padà lọ sí ilé.
negiketo cham e ngʼe pundegi kendo gidhi.
27 Níbi tí wọ́n ti dúró láti sùn lóru ọjọ́ náà, ọ̀kan nínú wọn tú àpò rẹ̀ láti mú oúnjẹ fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó sì rí owó rẹ̀ ní ẹnu àpò rẹ̀.
Kamane gibuore gotieno, achiel kuomgi nogonyo gunde mondo omi pundane chiemo, kendo noneno pesane ka otwe e dho ogunde.
28 Ó sì wí fún àwọn arákùnrin rẹ̀ pé, “a ti dá owó mi padà, òun nìyí ní ẹnu àpò mi.” Ẹ̀rù bà wọ́n, wọ́n sì ń gbọ̀n, wọ́n sì wí pé, “Èwo nìyí tí Ọlọ́run ṣe sí wa yìí.”
Nowacho nowetene niya, “Osedwokna pesana, eri go en e dho ogunda.” Chunygi nobwok ma gibedo moluor kagiwacho niya, “Angʼo ma Nyasaye osetimonwa ni?”
29 Nígbà tí wọ́n padà dé ọ̀dọ̀ Jakọbu baba wọn ní ilẹ̀ Kenaani, wọ́n ròyìn gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún un wí pé,
Kane gibiro ir Jakobo wuon-gi e piny Kanaan, neginyise duto mane osetimorenegi. Negiwacho niya,
30 “Ọkùnrin náà tí í ṣe alábojútó ilẹ̀ náà, sọ̀rọ̀ líle sí wa, ó sì fi ẹ̀sùn kàn wá pé a wá yọ́ ilẹ̀ náà wò ni.
“Ngʼat ma ruodh pinyno nowuoyo kodwa mager kendo nokawowa mana ka okwach kich modhi nono pinygi.
31 Ṣùgbọ́n, a wí fún un pé, ‘Rárá o, olóòtítọ́ ènìyàn ni wá, a kì í ṣe ayọ́lẹ̀wò.
To ne wawachone ni, ‘Wan joma kare; ok wan okwach kich.
32 Arákùnrin méjìlá ni wá, ọmọ baba kan náà, ọ̀kan ti kú, èyí tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn wà lọ́dọ̀ baba wa ni ilẹ̀ Kenaani.’
Ne wan yawuowi apar gariyo, yawuot ngʼat achiel. Achiel kuomwa nolal, kendo ma chogo to odongʼ gi wuonwa e piny Kanaan.’
33 “Nígbà náà ni ọkùnrin tí ó jẹ́ alábojútó ilẹ̀ náà wí fún wa pé, ‘Báyìí ni n ó ṣe mọ̀ bóyá olóòtítọ́ ènìyàn ni yín, ẹ fi ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin yín sílẹ̀ níbí, pẹ̀lú mi, ẹ sì mú oúnjẹ lọ fún àwọn ará ilé yín tí ebi ń pa kú lọ, lọ́wọ́ ìyàn.
“Eka ruodhno nowachonwa ni, ‘Ma e kaka abiro ngʼeyo kata ka un joma kare: Achiel kuomu odongʼ ka kendo joma odongʼ oter chiemo ne joodu makoro chandore ka.
34 Ṣùgbọ́n ẹ mú arákùnrin yín tí ó kéré jùlọ wá fún mi kí n le mọ̀ pé dájúdájú ẹ kì í ṣe ayọ́lẹ̀wò bí kò ṣe ènìyàn tòótọ́. Nígbà náà ni n ó mú arákùnrin yín padà fún un yín, lẹ́yìn náà ẹ le máa wá ṣe òwò bí ó ti wù yín ní ilẹ̀ yìí.’”
To kelnauru omeru ma chogo mondo mi abed gadiera ni ok un okwach kich to un joma kare. Eka anaduoknu owadu kendo ulok ohala e pinyni.’”
35 Bí wọ́n sì ti ń tú àpò ẹrù wọn, ẹnìkọ̀ọ̀kan bá owó tí ó san fún ọjà náà lẹ́nu àpò rẹ̀! Ẹ̀rù sì bà wọ́n gidigidi, àwọn àti baba wọn.
Kane gigonyo ogundegi, ngʼato ka ngʼato noyudo ofuku mar pesane e dho gunde! Kane gineno pesago, giduto ne gibuok ahinya kaachiel gi wuon-gi.
36 Jakọbu baba wọn wí fún wọn pé, “Ẹ ti mú mi pàdánù àwọn ọmọ mi. N kò rí Josẹfu mọ́, bẹ́ẹ̀ ni n kò sì rí Simeoni náà mọ. Ẹ sì tún fẹ́ mú Benjamini lọ. Èmi ni gbogbo ohun búburú yìí wá ń ṣẹlẹ̀ sí!”
Jakobo wuon-gi nowachonegi niya, “Usemaya nyithinda. Josef onge, kendo Simeon bende onge, kendo koro Benjamin bende udwaro maya. Gik moko duto ok nikare koda!”
37 Nígbà náà ni Reubeni wí fún baba rẹ̀ pé, “Pa àwọn ọmọ mi méjèèjì bí n kò bá mú Benjamini padà wá fún ọ, èmi ni kí o fà á lé lọ́wọ́, n ó sì mu un padà wá.”
Eka Reuben nowacho ne wuon-gi niya, “Inyalo nego yawuota ka ok aduogoni Benjamin. Weye e lweta kendo abiro duoge.”
38 Ṣùgbọ́n Jakọbu wí pé, “Ọmọ mi kì yóò bá a yín lọ, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ti kú, òun nìkan sì ni ó kù nínú àwọn ọmọ ìyá rẹ̀. Bí ohunkóhun bá ṣẹlẹ̀ sí i, ìbànújẹ́ ni yóò sì pa mi kú ni ọjọ́ ogbó mi yìí.” (Sheol h7585)
To Jakobo nodwoke niya, “Wuoda ok nyal dhi kuno kodu; owadgi osetho kendo en kende ema odongʼ, ka gimoro marach otimorene e wuodhno, to ubiro miyo atho gi kuyo.” (Sheol h7585)

< Genesis 42 >