< Genesis 38 >

1 Ní àkókò náà, Juda lọ kúrò lọ́dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀ láti lọ dúró lọ́dọ̀ ọkùnrin ará Adullamu kan tí ń jẹ́ Hira.
Hnin at vaengah tah Judah te a manuca rhoek taeng lamkah suntla tih Adullami hlang, a ming te Hirah taengah pah.
2 Juda sì pàdé ọmọbìnrin Kenaani kan níbẹ̀ ẹni ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣua. Ó sì fi ṣe aya, ó sì bá a lòpọ̀;
Te vaengah Judah loh Kanaan hoel nu, a ming ah Shua a hmuh hatah pahoi a loh tih a ih puei.
3 ó sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan, tí ó sọ orúkọ rẹ̀ ní Eri.
Te dongah pumrhih tih capa a cun vaengah a ming te Er a sak.
4 Ó sì tún lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin, ó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Onani.
Te phoeiah koep pumrhih tih ca a cun hatah a ming te Onan a sak.
5 Ó sì tún bí ọmọkùnrin mìíràn, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Ṣela. Ní Kesibu ni ó wà nígbà tí ó bí i.
Te phoeiah a rhaep bal tih capa a cun hatah a ming te Shelah a sak. Tedae Shelah a cun vaengah Kezib ah om.
6 Juda sì fẹ́ aya fún Eri, àkọ́bí rẹ̀, orúkọ aya náà ni Tamari.
Te phoeiah Judah loh a caming Er ham yuu a loh pah tih anih ming tah Tamar ni.
7 Ṣùgbọ́n Eri àkọ́bí Juda ṣe ènìyàn búburú níwájú Olúwa, Ọlọ́run sì pa á.
Tedae Judah kah a caming Er tah BOEIPA kah mikhmuh ah boethae la a om dongah anih te BOEIPA loh a duek sak.
8 Nígbà náà ni Juda wí fún Onani, “Bá aya arákùnrin rẹ lòpọ̀, kí o ṣe ojúṣe rẹ fun un gẹ́gẹ́ bí àbúrò ọkọ, kí ó ba à le bí ọmọ fún un ní orúkọ arákùnrin rẹ.”
Te dongah Judah loh Onan la, “Na maya yuu taengah kun lamtah anih te yucanah. Te phoeiah na maya ham a tii a ngan thoh pah,” a ti nah.
9 Ṣùgbọ́n Onani mọ̀ pé àwọn ọmọ náà kì yóò jẹ́ ti òun, nítorí náà ni gbogbo ìgbà tí ó bá wọlé tọ aya arákùnrin rẹ̀ lọ, ilẹ̀ ni ó ń da nǹkan ọkùnrin rẹ̀ sí, kí ó má bá a bímọ fún arákùnrin rẹ̀.
Tedae a tii a ngan te amah ham om hae mahpawh tila Onan loh a ming dongah, a maya yurho taengah a ih vaengah khaw diklai ah vik a san tih a maya ham tiingan khueh pah pawh.
10 Ohun tí ó ń ṣe yìí burú lójú Olúwa, ó sì pa òun náà pẹ̀lú.
Anih kah a saii te BOEIPA mikhmuh ah a lolh bal dongah anih khaw BOEIPA loh a duek sak.
11 Nígbà náà ni Juda wí fún Tamari, ìyàwó ọmọ rẹ̀ pé, “Lọ máa gbé bí opó ní ilé baba rẹ, títí tí Ṣela yóò fi dàgbà ó lérò pé òun náà lè kú bí àwọn arákùnrin rẹ̀ tókù.” Nígbà náà ni Tamari ń lọ gbé ilé baba rẹ̀.
Te vaengah Shelah khaw a maya rhoi bangla duek ve a ti. Te dongah Judah loh a langa Tamar la, “Ka capa Shelah a pantai hil tah na pa im ah nuhmai la khosa mai,” a ti nah. Te dongah Tamar khaw cet tih a napa im ah kho a sak.
12 Lẹ́yìn ìgbà pípẹ́, ìyàwó Juda, ọmọbìnrin Ṣua sì kú, nígbà tí ọjọ́ ọ̀fọ̀ Juda sì pé, ó gòkè lọ sí Timna, sí ọ̀dọ̀ àwọn tí ń bá a rẹ́run àgùntàn rẹ̀, Hira ará Adullamu tí í ṣe ọ̀rẹ́ rẹ̀ sì bá a lọ.
Tedae kum a yet phoeiah tah Judah yuu Shua nu te duek. Te dongah Judah khaw hal tih a tu mul aka vo neh a hui Adullami Hirah taengah Timnah la cet.
13 Nígbà tí ẹnìkan sọ fún Tamari pé, “Baba ọkọ ọ̀ rẹ̀ wà ní ọ̀nà àjò rẹ̀ sí Timna láti rẹ́run àgùntàn rẹ̀.”
Te dongah, “Tu mul vok ham Timnah la na marhang cet hang ke,” a ti na tih Tamar taengla a puen pah.
14 Ó bọ́ aṣọ opó rẹ̀, ó sì fi ìbòjú bo ojú ara rẹ̀ kí wọn má ba à mọ̀ ọ́n. Ó sì jókòó sí ẹnu-bodè Enaimu, èyí tí ó wà ní ọ̀nà Timna. Nítorí ó rí i wí pé, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Ṣela ti dàgbà, síbẹ̀, a kò fi òun fún un gẹ́gẹ́ bí aya.
Te vaengah Shelah khaw ham coeng dae anih yuu la n'khueh moenih tila Tamar loh a hmuh dongah amah dongkah nuhmai himbai te a dul. Te phoeiah hnii a yil, muei a thuh tih Timnah long kah Enaim thohka ah ngol.
15 Nígbà tí Juda rí i, ó rò pé panṣágà ni, nítorí ó ti bo ojú rẹ̀.
Tedae anih te Judah loh a hmuh vaengah a hmai a dah dongah pumyoi ni tila a poek.
16 Láìmọ̀ pé, aya ọmọ òun ní í ṣe, ó yà tọ̀ ọ́ ní ẹ̀bá ọ̀nà, ó wí pé, “Wá kí èmi kí ó lè wọlé tọ̀ ọ́.” Òun sì wí pé, “Kín ni ìwọ yóò fi fún mi kí ìwọ kó lè wọlé tọ̀ mí.”
Anih te amah langa la a ming pawt dongah long taengla anih taengah pah tih, “Halo, nang taengah ka ip ni ne,” a ti nah hatah, “Kai taengah na kun te kai ham balae na khueh eh,” a ti nah.
17 Ó sì wí pé, “Èmi yóò fi ọmọ ewúrẹ́ kan ránṣẹ́ sí ọ láti inú agbo ẹran.” Obìnrin náà sì dáhùn pé, “Ṣé ìwọ yóò fún mi ní ohun kan gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí títí tí ìwọ yóò fi fi ránṣẹ́?”
Te vaengah Judah loh, “Kamah loh boiva khuikah maae ca kan pat bit ni,” a ti nah. Tedae Tamar loh, “Nan pat hlanah hnohol han khueh dae,” a ti nah.
18 Juda sì bi í pé, “Ẹ̀rí wo ni kí n fún ọ?” Ó sì dáhùn pé, “Èdìdì ìdámọ̀ okùn àti ọ̀pá ìtìlẹ̀ rẹ ti ń bẹ ní ọwọ́ rẹ.” Ó sì kó wọn fún un, ó sì sùn tì í, obìnrin náà sì lóyún nípasẹ̀ rẹ̀.
Te dongah, “Hnohol te balae nang taengah kan paek eh?” a ti nah. Te vaengah, “Na kutbuen mai khaw, hamnak khaw, na kut kah conghol mai te khaw,” a ti nah. Te dongah anih te a paek tih a kun thil dongah Judah loh Tamar a vawn sak.
19 Lẹ́yìn ìgbà tí ó lọ, ó bọ́ ìbòjú ojú rẹ̀, ó sì tún wọ aṣọ opó rẹ̀ padà.
Te phoeiah thoo tih, cet tih a pum dongkah hnii te a dul phoeiah nuhmai himbai tloep a bai.
20 Juda sì rán ọmọ ewúrẹ́ náà láti ọwọ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀, ará Adullamu náà lọ láti gba ògo n nì wá lọ́wọ́ obìnrin náà. Ṣùgbọ́n wọn kò bá obìnrin náà níbẹ̀.
Te dongah huta kut kah hnohol te tlan ham Judah loh a hui Adullami hoel kut ah maae ca te a pat van hatah rhawp hmu pawh.
21 Ó béèrè lọ́wọ́ àwọn ènìyàn àdúgbò náà pé, “Níbo ni alágbèrè ojúbọ òrìṣà tí ó wà ní etí ọ̀nà Enaimu wà?” Wọ́n sì dá a lóhùn pé, “Kò sí alágbèrè ojúbọ òrìṣà kankan níbí.”
Te dongah te hmuen kah hlang rhoek te a dawt, “Enaim long taengkah hlanghalh te melae?” a ti nah vaengah, “He rhoek ah hlanghalh om pawh,” a ti na uh.
22 Ó sì padà lọ sọ́dọ̀ Juda ó wí fún un pé, “Èmí kò rí i, à ti pé àwọn aládùúgbò ibẹ̀ sọ pé kò sí alágbèrè ojúbọ òrìṣà kankan níbẹ̀.”
Te dongah Judah taengla koep bal tih, “Anih te ka hmuh moenih. Te phoeiah he hmuen kah hlang rhoek long khaw, ‘He rhoek ah hlanghalh a om moenih,’ a ti uh,” a ti nah.
23 Nígbà náà ni Juda wí pé, “Jẹ́ kí ó máa kó àwọn ohun tí ó wà lọ́wọ́ rẹ̀ lọ bí kò ṣe bẹ́ẹ̀ a ó di ẹlẹ́yà. Mo sá à fi ọmọ ewúrẹ́ ránṣẹ́ sí i, ṣùgbọ́n ìwọ kò rí òun.”
Te dongah Judah loh, “Amah neh amah te khoem uh saeh, nueihbu la n'om uh ve. Maae ca n'thak he khaw anih te na hmuh voel pawt tih he,” a ti nah.
24 Lẹ́yìn nǹkan bí oṣù mẹ́ta, wọn sọ fún Juda pé, “Tamari aya ọmọ rẹ̀ ṣe àgbèrè, ó sì ti lóyún.” Juda sì wí pé, “Ẹ mú un jáde, kí ẹ sì dá iná sun ún.”
Tedae hla thum tluk a lo vaengah Judah taengah, “Nang langa Tamar te cukhalh tih pumyoihnah neh vawn lah ko te,” a ti nah tih a puen pa uh hatah Judah loh, “Anih te khuen uh lamtah hoeh,” a ti nah.
25 Bí wọ́n sì ti ń mú un jáde, ó ránṣẹ́ sí baba ọkọ rẹ̀ pé, “Ọkùnrin tí ó ni àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ó fún mi lóyún. Wò ó, bóyá o lè mọ ẹni tí ó ni èdìdì ìdámọ̀, okùn àti ọ̀pá ìtìlẹ̀ wọ̀nyí.”
Anih te a mawt uh van hatah, “He rhoek he u hlang kah nim. Kai khaw tekah hlang hut la ka vawn dongah hekah kutnoek, hamnak neh conghol, ukah nim tila hmat lah saeh,” a ti nah tih a marhang taengla Tamar loh a pat.
26 Juda sì dá wọn mọ̀, ó sì wí pé, “O ṣe olódodo jù mí lọ, níwọ̀n ìgbà tí n kò fi fún Ṣela ọmọ mi.” Kò sì bá a lòpọ̀ mọ́ láti ọjọ́ náà.
Tedae Judah loh a hmat vaengah, “Ka capa Shelah te anih ka paek pawt dongah te kai lakah anih tang coeng,” a ti. Te dongah anih ming ham koep khoep voel pawh.
27 Nígbà tí àsìkò ìbímọ rẹ̀ tó. Ìbejì ọkùnrin ni ó bí.
Tedae ca-om tue vaengah tah a bung khuiah caphae rhoi la tarha om.
28 Bí ó sì ti ń bímọ, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ náà na ọwọ́ jáde; agbẹ̀bí sì so okùn òdòdó mọ́ ọmọ náà ní ọrùn ọwọ́. Ó sì wí pé, “Èyí ni o kọ́kọ́ jáde.”
Te dongah camoe a om vaengah kut pakhat te han thawt dongah ca-om loh a tuuk tih, a kut dongah a lingdik a cin pah tih, “Lamhma la om coeng he,” a ti.
29 Ṣùgbọ́n nígbà tí ó fa ọwọ́ rẹ̀ padà, èkejì rẹ̀ jáde. Tamari sì wí pé, “Níbo ni ìwọ ti wá?” Ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Peresi.
Tedae a kut vik a yueh tih a mana lat ha thoeng dongah, “Namah loh a puut metlamlae nam va,” a ti nah dongah a ming te Perez a sak.
30 Nígbà náà ni èkejì tí a ti so okùn olódòdó mọ́ lọ́rùn ọwọ́ jáde, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ni Sera.
Te phoeiah a kut dongah a lingdik aka om a maya te ha pawk tih a ming te Zerah a sak.

< Genesis 38 >