< Genesis 36 >
1 Wọ̀nyí ni ìran Esau, ẹni tí a ń pè ní Edomu.
Na rĩrĩ, ũyũ nĩguo ũhoro wa Esaũ (na nowe Edomu).
2 Nínú àwọn ọmọbìnrin Kenaani ni Esau ti fẹ́ àwọn ìyàwó rẹ̀: Adah ọmọbìnrin Eloni ará Hiti àti Oholibama, ọmọbìnrin Ana, ọmọ ọmọ Sibeoni ará Hifi.
Esaũ ahikirie atumia ake kuuma kũrĩ andũ-a-nja a Kaanani: Ada aarĩ mwarĩ wa Eloni ũrĩa Mũhiti, na Oholibama mwarĩ wa Ana ũrĩa warĩ mwarĩ wa Zibeoni ũrĩa Mũhivi,
3 Ó sì tún fẹ́ Basemati ọmọ Iṣmaeli arábìnrin Nebaioti.
o na ningĩ Basemathu ũrĩa warĩ mwarĩ wa Ishumaeli na mwarĩ wa nyina na Nebaiothu.
4 Adah bí Elifasi fún Esau, Basemati sì bí Reueli,
Ada agĩciarĩra Esaũ Elifazu, na Basemathu agĩciara Reueli,
5 Oholibama pẹ̀lú sì bí Jeuṣi, Jalamu, àti Kora. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ tí Esau bí ní Kenaani.
nake Oholibama agĩciara Jeushu, na Jalamu na Kora. Acio nĩo maarĩ ariũ a Esaũ, arĩa aaciarĩirwo kũu Kaanani.
6 Esau sì mú àwọn aya rẹ̀, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ àti gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, àwọn ohun ọ̀sìn rẹ̀ àti àwọn ẹran ọ̀sìn mìíràn àti gbogbo ohun ìní mìíràn tí ó ní, ni Kenaani, ó sì kó lọ sí ilẹ̀ mìíràn, jìnà sí ibi tí Jakọbu arákùnrin rẹ̀ wà.
Na rĩrĩ, Esaũ akĩoya atumia ake na ariũ ake na airĩtu ake na andũ othe a nyũmba yake, o na mahiũ make na nyamũ iria ingĩ ciake, na indo ciothe iria aagĩte nacio kũu Kaanani, na agĩthiĩ bũrũri waraihanĩrĩirie na mũrũ wa nyina Jakubu.
7 Ohun ìní wọn pọ̀ ju èyí tí àwọn méjèèjì lè máa gbé ní ojú kan lọ. Ilẹ̀ tí wọ́n wà kò le gba àwọn méjèèjì nítorí àwọn ohun ọ̀sìn wọn.
Indo ciao ciarĩ nyingĩ mũno ũndũ matangĩahotire gũikarania hamwe; bũrũri ũrĩa maatũũraga ndũngĩahotire kũmaigana eerĩ nĩ ũndũ wa mahiũ mao.
8 Báyìí ni Esau (tí a tún mọ̀ sí Edomu) tẹ̀dó sí àwọn orílẹ̀-èdè olókè tí Seiri.
Nĩ ũndũ ũcio Esaũ (na nowe Edomu) agĩthiĩ gũtũũra bũrũri wa irĩma wa Seiru.
9 Èyí ni ìran Esau baba àwọn ará Edomu ní àwọn orílẹ̀-èdè olókè Seiri.
Ũyũ nĩguo ũhoro wa Esaũ ithe wa andũ a Edomu kũu bũrũri-inĩ wa irĩma wa Seiru.
10 Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Esau: Elifasi ọmọ Adah aya Esau àti Reueli, ọmọ Basemati tí í ṣe aya Esau pẹ̀lú.
Maya nĩmo marĩĩtwa ma ariũ a Esaũ: nĩ Elifazu, mũrũ wa Ada mũtumia wa Esaũ, na Reueli, mũrũ wa Basemathu mũtumia wa Esaũ.
11 Àwọn ọmọ Elifasi ni ìwọ̀nyí: Temani, Omari, Sefi, Gatamu, àti Kenasi.
Ariũ a Elifazu nĩ aya: nĩ Temani, na Omari, na Zefo, na Gatamu, na Kenazu.
12 Elifasi ọmọ Esau sì tún ní àlè tí a ń pè ní Timna pẹ̀lú, òun ló bí Amaleki fún un. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ ọmọ Adah aya Esau.
Elifazu mũrũ wa Esaũ o nake nĩ aarĩ na thuriya yetagwo Timina, ĩrĩa yamũciarĩire Amaleki. Acio nĩo maarĩ ariũ a mũrũ wa Ada mũtumia wa Esaũ.
13 Àwọn ọmọ Reueli: Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa. Àwọn ni ọmọ ọmọ Basemati aya Esau.
Ariũ a Reueli nĩ aya: nĩ Nahathu, na Zera, na Shama, na Miza. Acio nĩo maarĩ ariũ a mũrũ wa Basemathu mũtumia wa Esaũ.
14 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Oholibama ọmọbìnrin Ana ọmọ ọmọ Sibeoni: tí ó bí fún Esau: Jeuṣi, Jalamu àti Kora.
Ariũ a Esaũ arĩa aaciarĩirwo nĩ Oholibama mũtumia wake mwarĩ wa Ana ũrĩa warĩ mwarĩ wa Zibeoni: nĩ Jeushu, na Jalamu, na Kora.
15 Àwọn wọ̀nyí ni olórí nínú àwọn ọmọ Esau: àwọn ọmọ Elifasi, àkọ́bí Esau, Temani, Omari, Sefi, Kenasi,
Nao aya nĩo maarĩ anene thĩinĩ wa njiaro cia Esaũ: Ariũ a Elifazu irigithathi rĩa Esaũ: Anene maarĩ Temani, na Omari, na Zefo, na Kenazu,
16 Kora, Gatamu àti Amaleki. Àwọn wọ̀nyí ló jẹ́ olórí ìdílé tí ó ti ọ̀dọ̀ Elifasi ní Edomu wá, wọ́n jẹ́ ọmọ ọmọ Adah.
na Kora, na Gatamu, na Amaleki. Acio nĩo anene arĩa Elifazu aaciarĩire kũu Edomu; maarĩ a mũrũ wa Ada.
17 Wọ̀nyí sì ni àwọn ọmọ Esau, ọmọ Rueli: Nahati olórí, Sera olórí, Ṣamma olórí, Missa olórí. Àwọn wọ̀nyí ló jẹ́ olórí ìdílé tí ó ti ọ̀dọ̀ Reueli jáde ní Edomu. Ọmọ ọmọ Basemati aya Esau ni wọ́n jẹ́.
Ariũ a Reueli mũrũ wa Esaũ: Anene maarĩ Nahathu, na Zera, na Shama, na Miza. Aya nĩo anene arĩa Reueli aaciarĩire kũu Edomu; maarĩ a mũrũ wa Basemathu mũtumia wa Esaũ.
18 Àwọn ọmọ Oholibama aya Esau: Jeuṣi, Jalamu, àti Kora, àwọn wọ̀nyí ló jẹ́ olórí ìdílé tí ó ti ọ̀dọ̀ Oholibama ọmọ Ana, ìyàwó Esau wá.
Ariũ a Oholibama mũtumia wa Esaũ: Anene maarĩ Jeushu, na Jalamu, na Kora. Aya nĩo anene arĩa maaciarirwo nĩ Oholibama mũtumia wa Esaũ mwarĩ wa Ana.
19 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Esau (ti o túmọ̀ sí Edomu). Àwọn wọ̀nyí ni olórí wọn.
Aya nĩo maarĩ ariũ a Esaũ (na nowe Edomu), na acio nĩo maarĩ anene ao.
20 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Seiri ará Hori tí ó ń gbé ní ilẹ̀ náà: Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana,
Aya nĩo maarĩ ariũ a Seiru ũrĩa Mũhori arĩa maatũũraga bũrũri ũcio: Lotani, na Shobali, na Zibeoni, na Ana,
21 Diṣoni, Eseri, àti Diṣani, àwọn wọ̀nyí olórí ènìyàn Hori, àwọn ọmọ Seiri ni ilẹ̀ Edomu.
na Dishoni, na Ezeri, na Dishani. Ariũ acio a Seiru nĩo maarĩ anene a Ahori kũu Edomu.
22 Àwọn ọmọ Lotani: Hori àti Homamu: Timna sì ni arábìnrin Lotani.
Ariũ a Lotani maarĩ: Hori, na Homani. Timina aarĩ mwarĩ wa nyina na Lotani.
23 Àwọn ọmọ Ṣobali: Alifani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu.
Ariũ a Shobali maarĩ: Alivani, na Manahathu, na Ebali, na Shefo, na Onamu.
24 Àwọn ọmọ Sibeoni: Aiah àti Ana. Èyí ni Ana tí ó rí ìsun omi gbígbóná ní inú aginjù bí ó ti ń da àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Ṣebeoni baba rẹ̀.
Ariũ a Zibeoni maarĩ: Aia, na Ana. Ũyũ nĩwe Ana ũrĩa wonire ithima cia maaĩ mahiũ werũ-inĩ rĩrĩa arĩithagia ndigiri cia ithe Zibeoni.
25 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Ana: Diṣoni àti Oholibama ọmọbìnrin Ana.
Ciana cia Ana ciarĩ: Dishoni, na Oholibama mwarĩ wa Ana.
26 Àwọn ọmọ Diṣoni ni: Hemdani, Eṣbani, Itrani àti Kerani.
Ariũ a Dishoni maarĩ: Hemudani, na Eshibani, na Itharani, na Cherani.
27 Àwọn ọmọ Eseri: Bilhani, Saafani àti Akani.
Ariũ a Ezeri maarĩ: Bilihani, na Zaavani, na Akani.
28 Àwọn ọmọ Diṣani ni: Usi àti Arani.
Ariũ a Dishani maarĩ Uzu, na Arani.
29 Àwọn wọ̀nyí ni olórí ìdílé Hori: Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana,
Aya nĩo maarĩ anene a Ahori: nĩ Lotani, na Shobali, na Zibeoni, na Ana,
30 Diṣoni Eseri, àti Diṣani. Àwọn ni olórí ìdílé àwọn ará Hori gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn ní ilẹ̀ Seiri.
na Dishoni, na Ezeri, na Dishani. Acio nĩo maarĩ anene a Ahori, kũringana na ikundi ciao kũu bũrũri wa Seiru.
31 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli:
Aya nĩo maarĩ athamaki arĩa maathamakaga Edomu o mbere ya Isiraeli gũtanagĩa na mũthamaki o na ũmwe:
32 Bela ọmọ Beori jẹ ní Edomu. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
Bela mũrũ wa Beori nĩwe watuĩkire mũthamaki wa Edomu. Itũũra rĩake inene rĩetagwo Dinihaba.
33 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Rĩrĩa Bela aakuire, Jobabu mũrũ wa Zera wa kuuma Bozira agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.
34 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Rĩrĩa Jobabu aakuire, Hushamu wa kuuma bũrũri wa Atemani agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.
35 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
Rĩrĩa Hushamu aakuire, Hadadi mũrũ wa Bedadi, ũrĩa wahootire Midiani kũu bũrũri wa Moabi, agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake. Itũũra rĩake inene rĩetagwo Avithu.
36 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Rĩrĩa Hadadi aakuire, Samala wa kuuma Masereka agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.
37 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti, létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Rĩrĩa Samala aakuire, Shauli wa kuuma Rehobothu, kũu gũkuhĩ na Rũũĩ rwa Farati, agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.
38 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Rĩrĩa Shauli aakuire, Baali-Hanani mũrũ wa Akibori agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.
39 Nígbà tí Baali-Hanani ọmọ Akbori kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau, orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
Rĩrĩa Baali-Hanani mũrũ wa Akibori aakuire, Hadadi agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake. Itũũra rĩake inene rĩetagwo Pau, na mũtumia wake eetagwo Mehetabeli mwarĩ wa Matiredi, ũrĩa warĩ mwarĩ wa Mezahabu.
40 Àwọn wọ̀nyí ni orúkọ àwọn baálẹ̀ tí ó ti ọ̀dọ̀ Esau jáde wá, ní orúkọ ìdílé wọn, bí ìpínlẹ̀ wọn ti rí: baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti.
Aya nĩo maarĩ anene kuuma kũrĩ njiaro cia Esaũ, kũringana na marĩĩtwa mao, na mĩhĩrĩga, na ngʼongo ciao: Timina, na Aliva, na Jethethu,
41 Baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni,
na Oholibama, na Ela, na Pinoni,
42 baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
na Kenazu, na Temani, na Mibizaru,
43 Magdieli, àti Iramu. Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu, gẹ́gẹ́ bí wọn ti tẹ̀dó sí ilẹ̀ tí wọ́n gbà. Èyí ni Esau baba àwọn ará Edomu.
na Magidieli, na Iramu. Acio nĩo maarĩ anene a Edomu, kũringana na kũrĩa maatũũraga bũrũri-inĩ ũrĩa watuĩkĩte wao. Esaũ ũcio nĩwe warĩ ithe wa andũ a Edomu.