< Genesis 33 >
1 Jakọbu sì gbójú sókè, ó sì rí Esau àti irinwó ọkùnrin tí wọ́n ń bọ̀, ó sì pín àwọn ọmọ fún Lea, Rakeli àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin méjèèjì.
Na rĩrĩ, Jakubu agĩtiira maitho, akĩona Esaũ agĩũka arĩ na andũ ake magana mana; nĩ ũndũ ũcio akĩgayania ciana kũrĩ Lea na Rakeli na kũrĩ ndungata iria igĩrĩ cia andũ-a-nja.
2 Ó sì ti àwọn ìránṣẹ́bìnrin àti àwọn ọmọ wọn síwájú, Lea àti àwọn ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọ̀wọ́ kejì tí ó tẹ̀lé wọn, Rakeli àti Josẹfu sì wà lẹ́yìn pátápátá.
Akĩiga ndungata cia andũ-a-nja na ciana ciacio mbere, nake Lea na ciana ciake makĩrũmĩrĩra, nake Rakeli na Jusufu makĩrigia thuutha.
3 Jakọbu fúnra rẹ̀ wa lọ síwájú pátápátá, ó sì tẹríba ní ìgbà méje bí ó ti ń súnmọ́ Esau, arákùnrin rẹ̀.
Nake we mwene akĩmatongoria, na rĩrĩa aakuhĩrĩirie mũrũ wa nyina, akĩinamĩrĩra, agĩturumithia ũthiũ wake thĩ maita mũgwanja.
4 Ṣùgbọ́n Esau sáré pàdé Jakọbu, ó sì dì mọ́ ọn, ó rọ̀ mọ́ ọn lọ́rùn, ó sì fẹnukò ó lẹ́nu. Àwọn méjèèjì sì sọkún.
No Esaũ akĩhanyũka agatũnge Jakubu na akĩmũnyiita, akĩmũhĩmbĩria, akĩmũmumunya. Nao makĩrĩranĩra.
5 Nígbà tí Esau sì ṣe àkíyèsí àwọn ìyàwó àti ọmọ Jakọbu, ó béèrè lọ́wọ́ Jakọbu pé, “Ti ta ni àwọn wọ̀nyí?” Jakọbu sì fèsì wí pé, “Èyí ni àwọn ọmọ tí Ọlọ́run nínú àánú rẹ̀ ti fi fún ìránṣẹ́ rẹ.”
Ningĩ Esaũ agĩtiira maitho akĩona atumia na ciana. Akĩũria Jakubu atĩrĩ, “Andũ aya mũrĩ nao nĩ a ũ?” Jakubu agĩcookia atĩrĩ, “Ici nĩ ciana iria Ngai aheete ndungata yaku nĩ ũndũ wa ũtugi wake.”
6 Nígbà náà ni àwọn ìránṣẹ́bìnrin àti àwọn ọmọ wọn súnmọ́ tòsí, wọ́n sì tẹríba.
Hĩndĩ ĩyo ndungata icio cia andũ-a-nja na ciana ciacio igĩkuhĩrĩria na makĩinamĩrĩra.
7 Lẹ́yìn náà ni Lea àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀lú dé, wọ́n sì tún tẹríba. Ní ìkẹyìn ni Josẹfu àti Rakeli dé, wọ́n sì tún tẹríba pẹ̀lú.
Lea na ciana ciake makĩrũmĩrĩra, magĩũka na makĩinamĩrĩra. Marigĩrĩrio, Jusufu na Rakeli magĩũka, o nao makĩinamĩrĩra.
8 Esau sì béèrè pé, “Kí ni èrò rẹ tí o fi to àwọn ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ tí mo pàdé wọ̀nyí?” Jakọbu dáhùn pé, “Kí n ba le rí ojúrere rẹ ni olúwa mi.”
Esaũ akĩũria atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩtũmi gĩa kũndũmĩra ikundi icio ndatũnga?” Nake Jakubu agĩcookia atĩrĩ, “Nĩgeetha njĩtĩkĩrĩke maitho-inĩ maku, wee mwathi wakwa.”
9 Ṣùgbọ́n Esau wí pé, “Tèmi ti tó mi, pa èyí tí o ní mọ́ fún ara rẹ.”
No Esaũ akiuga atĩrĩ, “Mũrũ wa maitũ, niĩ ndĩ na indo cia kũnjigana. Ikara na icio ũrĩ nacio wee mwene.”
10 Jakọbu bẹ̀ ẹ́ wí pé, “Rárá bẹ́ẹ̀ kọ́, bí ó bá ṣe pé, mo rí ojúrere rẹ, jọ̀wọ́ gba ọrẹ lọ́wọ́ mi. Bí mo ṣe rí ojú rẹ̀ yìí, ó dàbí wí pé mo rí ojú Ọlọ́run ni báyìí, tí inú rẹ̀ ti dùn sí mi.
Jakubu akiuga atĩrĩ, “Aca, ndagũthaitha! Angĩkorwo nĩnjĩtĩkĩrĩkĩte maitho-inĩ maku-rĩ, amũkĩra kĩheo gĩkĩ kuuma kũrĩ niĩ. Nĩ ũndũ kuona ũthiũ waku no ta kuona ũthiũ wa Ngai, tondũ nĩ wanyamũkĩra na gĩkeno.
11 Jọ̀wọ́ gba àwọn ohun tí mo mú wá wọ̀nyí lọ́wọ́ mi. Nítorí Ọlọ́run ti fi oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ hàn sí mi, gbogbo ohun tí mo fẹ́ sì ni mo ní.” Nígbà tí Jakọbu sì rọ̀ ọ́ pé Esau gbọdọ̀ gbà wọ́n, Esau sì gbà á.
Ndagũthaitha ĩtĩkĩra kĩheo kĩu ũreheirwo, tondũ Ngai nĩanjĩkĩte wega, na ndĩ na indo cia kũnjigana.” Na tondũ Jakubu nĩamũringĩrĩirie-rĩ, Esaũ agĩciĩtĩkĩra.
12 Nígbà náà ni Esau wí pé, “Jẹ́ kí a máa lọ, n ó sìn ọ.”
Ningĩ Esaũ akĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩtũthiĩ; nĩngũtwarana nawe.”
13 Ṣùgbọ́n Jakọbu wí fún un pé, “Ṣe ìwọ náà ṣe àkíyèsí pé ọ̀pọ̀ nínú àwọn ọmọ wọ̀nyí kéré, àwọn màlúù àti àgùntàn pẹ̀lú sì ní àwọn ọmọ kéékèèké. Bí a bá dà wọ́n rìn jìnnà ju bí agbára wọn ṣe mọ lọ, wọ́n lè kú.
No Jakubu akĩmwĩra atĩrĩ, “Mwathi wakwa nĩoĩ atĩ twana tũtũ tũtirĩ na hinya, na no nginya menyerere ngʼondu na ngʼombe iria irongithia. Ingĩtwarwo na ihenya o na mũthenya ũmwe, nyamũ ciothe no ikue.
14 Èmi bẹ̀ ọ́, máa lọ síwájú ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ó sì máa rọra bọ̀, títí èmi àti àwọn ọmọ yóò fi dé ọ̀dọ̀ olúwa mi ní Seiri.”
Nĩ ũndũ ũcio mwathi wakwa nĩathiiage mbere ya ndungata yake, na niĩ thiĩ o kahora kũringana na mũthiĩre wa ikundi ici, o na wa ciana, nginya rĩrĩa ngaakinya kwa mwathi wakwa kũu Seiru.”
15 Esau wí pé, “Jẹ́ kí n fi díẹ̀ sílẹ̀ fún ọ nínú àwọn ọkùnrin mi nígbà náà.” Jakọbu wí pé, “Èéṣe, àní kí n sá à rí ojúrere olúwa mi?”
Esaũ akĩmwĩra atĩrĩ, “No kĩreke ngũtigĩre ndungata imwe ciakwa.” Jakubu akĩmũũria atĩrĩ, “Ũgwĩka ũguo nĩkĩ? Reke niĩ njĩtĩkĩrĩke maitho-inĩ ma mwathi wakwa.”
16 Ní ọjọ́ náà gan an ni Esau padà lọ sí Seiri.
Nĩ ũndũ ũcio Esaũ akĩhũndũka mũthenya o ro ũcio agĩthiĩ arorete Seiru.
17 Jakọbu sì lọ sí Sukkoti, ó sì kọ́ ilé fún ara rẹ̀, ó sì ṣe ọgbà fún àwọn ẹran. Ìdí èyí ní a fi ń pe ibẹ̀ ní Sukkoti.
Nowe Jakubu, agĩthiĩ Sukothu, kũrĩa eyakĩire nyũmba, na agĩthondeka ciugũ cia mahiũ make. Nĩkĩo handũ hau hetagwo Sukothu.
18 Lẹ́yìn ìgbà tí Jakọbu tí Padani-Aramu dé, àlàáfíà ni Jakọbu dé ìlú Ṣekemu ní ilẹ̀ Kenaani, ó sì pàgọ́ sí itòsí ìlú náà.
Thuutha wa Jakubu kuuma Padani-Aramu, agĩkinya o wega itũũra-inĩ rĩrĩa inene rĩa Shekemu kũu Kaanani, na akĩamba hema hakuhĩ na itũũra rĩu inene.
19 Ó sì ra ilẹ̀ kan tí ó pàgọ́ sí ni ọgọ́rùn-ún owó fàdákà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Hamori tí í ṣe baba Ṣekemu.
Nake akĩgũra gĩcunjĩ kĩa mũgũnda na betha igana rĩmwe kuuma kũrĩ ariũ a Hamoru ithe wa Shekemu, harĩa aambire hema yake.
20 Níbẹ̀ ni ó gbé tẹ́ pẹpẹ kan tí ó pè ní El Elohe Israẹli.
Agĩaka kĩgongona handũ hau, na agĩgĩĩta Eli-Elohe-Isiraeli.