< Genesis 26 >

1 Ìyàn kan sì mú ní ilẹ̀ náà, yàtọ̀ fún èyí tí ó mú ní ìgbà ayé Abrahamu, Isaaki sì lọ sọ́dọ̀ Abimeleki ọba àwọn Filistini ni Gerari.
Lao esa, hambu ndoe-laꞌas manaseliꞌ sia nusaꞌ naa, onaꞌ ndoe-laꞌas leleꞌ Abraham feꞌe masodꞌaꞌ. Dadꞌi Isak neu noꞌe isin sia Abimelek, atahori Filistin ra mane na, fo eni bisa leo sia Gerar.
2 Olúwa sì fi ara han Isaaki, ó sì wí pé, “Má ṣe sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti, jókòó ní ilẹ̀ tí èmi ó fún ọ.
Ana tao taꞌo naa, huu LAMATUALAIN natudꞌu Ao na neu e nae, “Afiꞌ muu sia Masir. Dei fo Au utudꞌu nggo mamana feaꞌ.
3 Máa ṣe àtìpó ní ilẹ̀ yìí fún ìgbà díẹ̀, èmi ó sì wà pẹ̀lú rẹ, èmi yóò sì bùkún fún ọ. Nítorí ìwọ àti irú-ọmọ rẹ ni èmi yóò fi gbogbo àwọn ilẹ̀ wọ̀nyí fún, èmi yóò sì fi ìdí ìbúra tí mo ṣe fún Abrahamu baba rẹ múlẹ̀.
Mete ma ho leo manumban sia mamanaꞌ naa, naa, Au o nggo, ma fee nggo papala-babꞌanggiꞌ mataꞌ-mataꞌ. Au tao tititi-nonosi mara ramahefu, onaꞌ nduuꞌ sia lalai a. Au fee nggo mo tititi-nonosi mara mamanaꞌ ia no basa nusa nara. Mia tititi-nonosi mara, basa atahori raefafoꞌ a hambu papala-babꞌanggiꞌ. No naa, Au tao utetu hehelu-fufuli ngga o amam Abraham.
4 Èmi yóò sọ ìran rẹ di púpọ̀ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, èmi yóò sì fi gbogbo ilẹ̀ yìí fún irú àwọn ọmọ rẹ, àti nípasẹ̀ irú-ọmọ rẹ ni a ó bùkún fún gbogbo orílẹ̀-èdè ayé,
5 nítorí tí Abrahamu gba ohùn mi gbọ́, ó sì pa gbogbo ìkìlọ̀, àṣẹ, ìlànà àti òfin mi mọ́.”
Au tao basa ia ra, huu amam tungga hihii Ngga, parenda Ngga, ma dala Ngga.”
6 Nítorí náà Isaaki jókòó ní Gerari.
De Isak leo manumban sia Gerar.
7 Nígbà tí àwọn ọkùnrin ìlú náà bi í léèrè ní ti aya rẹ̀, ó sì wí pé, “Arábìnrin mi ní í ṣe,” nítorí tí ó bẹ̀rù láti jẹ́wọ́ wí pé, “Aya mi ni.” Ó ń rò wí pé, “Kí àwọn ọkùnrin ibẹ̀ náà má ba à pa mí nítorí Rebeka, nítorí tí òun ní ẹwà púpọ̀.”
Ribka, meulau na seli. Dadꞌi atahori sia naa ra rita e ma, ara ratatane e. Te Isak nataa nae, “Ribka ia, au odꞌi ngga.” Ana namatau mete ma eni nataa nae sao na, neꞌo atahori ra tao risa e fo haꞌi rala Ribka.
8 Nígbà tí Isaaki sì ti wà níbẹ̀ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́, Abimeleki ọba Filistini yọjú lójú fèrèsé, ó sì rí Isaaki ń bá Rebeka aya rẹ̀ tage.
Isak leo dodꞌoo sia naa ena ma, lao esa maneꞌ a nakaloloik mia jendela, ma nita Isak holu ma idꞌu Ribka.
9 Nígbà náà ni Abimeleki ránṣẹ́ pe Isaaki ó sì wí fun pé, “Nítòótọ́, aya rẹ ni obìnrin yìí í ṣe, èéṣe tí ìwọ fi wí fún wa pé arábìnrin mi ni?” Isaaki sì fèsì pé, “Nítorí mo rò pé mo le pàdánù ẹ̀mí mi nítorí rẹ̀.”
Boe ma ana denu atahori roꞌe Isak, de natane e nae, “Isak! Inaꞌ naa, sao ma! Saa de mae, ho odꞌim?” Isak nataa nae, “Taꞌo ia, amaꞌ! Au umutau mete ma ae eni, au sao ngga, afiꞌ losa atahori ra tao risa au.”
10 Nígbà náà ni Abimeleki dáhùn pé, “Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa yìí? Bí ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn wọ̀nyí bá ti bá a lòpọ̀ ń kọ́? Ìwọ ìbá wá mú ẹ̀bi wá sórí wa.”
Maneꞌ a nataa nae, “Mete ma atahori sia ia sungguꞌ ro sao ma naa, ho fee salaꞌ neu hai! Taꞌo bee de ho tao taꞌo naa neu hai?”
11 Nígbà náà ni Abimeleki pàṣẹ fún gbogbo ènìyàn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan ọkùnrin yìí tàbí aya rẹ̀ yóò jẹ̀bi ikú.”
Basa ma, Abimelek fee nesenenedꞌaꞌ neu rauinggu nara nae, “Misinedꞌa malolole! Hei seka mimbirani ngganggu atahori ia, do sao na, naa, au hukun isa nggi.”
12 Ní ọdún náà, Isaaki gbin ohun ọ̀gbìn sí ilẹ̀ náà, ó sì kórè rẹ̀ ní ìlọ́po ọgọ́rùn-ún ọdún ni ọdún kan náà, nítorí Olúwa bùkún un.
Leleꞌ naa, Isak sela-nggari sia nusaꞌ naa. Ana hambu baliꞌ buna-bꞌoa na lao natun esa, huu LAMATUALAIN fee ne papala-babꞌanggiꞌ.
13 Ọkùnrin náà sì di ọlọ́rọ̀ púpọ̀, ọrọ̀ rẹ̀ sì ń pọ̀ si, títí ó fi di ènìyàn ńlá.
Ana bau namasuꞌi, losa namasuꞌi raranggi.
14 Ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹran ọ̀sìn àti agbo ẹran àti àwọn ìránṣẹ́ tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn Filistini ń ṣe ìlara rẹ̀.
Sapi, bibꞌi, ma hiek nara, boe ramahefu. Ana mana tao ues nara o, hetar boe. De atahori Filistin ra rala nara mera mbali e.
15 Nítorí náà àwọn ará Filistini ru erùpẹ̀ di gbogbo kànga tí àwọn ìránṣẹ́ Abrahamu baba rẹ̀ ti gbẹ́.
Maꞌahulu naa, Isak aman Abraham se ali oe mataꞌ naeꞌ. Te ia naa, atahori Filistin ra mbori raꞌateme oe mataꞌ ra no rae.
16 Nígbà náà ni Abimeleki wí fún Isaaki pé, “Jáde kúrò ní ilẹ̀ wa, nítorí tí ìwọ ti di alágbára púpọ̀ jù wá lọ.”
Boe ma mane Abimelek olaꞌ no Isak nae, “Isak! Malole lenaꞌ, ho lao hela nusaꞌ ia leo. Te koasa ma lenaꞌ hai ena.”
17 Isaaki sì ṣí kúrò níbẹ̀, ó sì pàgọ́ sí àfonífojì Gerari ó sì ń gbé ibẹ̀.
Basa de, Isak lao hela naa, de neu leo baliꞌ sia lololoꞌ Gerar.
18 Isaaki sì ṣe àtúngbẹ́ àwọn kànga tí Abrahamu baba rẹ̀ ti gbẹ́ nígbà ayé rẹ̀, èyí tí àwọn Filistini ti dí lẹ́yìn ikú Abrahamu baba rẹ̀, ó sì fún wọn lórúkọ tí baba rẹ̀ ti sọ wọ́n tẹ́lẹ̀.
Ana ali baliꞌ oe mataꞌ, fo ara tatanaꞌ ra. Ana babꞌae oe mataꞌ ra, tungga nara-naraꞌ fo ama na babꞌae nalaꞌ ra.
19 Àwọn ìránṣẹ́ Isaaki sì gbẹ́ kànga ní àfonífojì náà, wọ́n kan ìsun omi níbẹ̀.
Isak ate nara ali oe mataꞌ sia lololoꞌ Gerar ma, ara ali dai oe a mata na, de nasapupuraꞌ dea neu.
20 Ṣùgbọ́n àwọn darandaran Gerari ń bá àwọn darandaran Isaaki jà sí kànga náà pé àwọn ni àwọn ni í. Nítorí náà ni ó fi pe orúkọ kànga náà ní Eseki, nítorí pé wọ́n bá a jà sí kànga náà.
Te Gerar manatadꞌa nara rareresi ro Isak manatadꞌa nara, huu oe mataꞌ naa. Ara rae, “Ia hai oe ma!” Naa de, Isak babꞌae oe mataꞌ naa Esek, sosoa na ‘rareresi’.
21 Àwọn ìránṣẹ́ Isaaki tún gbẹ́ kànga mìíràn, wọ́n sì tún jà nítorí rẹ̀ pẹ̀lú, ó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Sitna.
Basa ma, Isak atahori nara ali seluꞌ oe mataꞌ esa fai. Te ara rareresi fai, huu oe mataꞌ naa. Naa de, Isak babꞌae oe mataꞌ naa, Sitna, sosoa na ‘balabꞌan’.
22 Ó sì tún kúrò níbẹ̀, ó sì gbẹ́ kànga mìíràn, wọn kò sì jásí èyí rárá, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Rehoboti, ó wí pé, “Nísinsin yìí, Olúwa ti fi ààyè gbà wá, a ó sì gbilẹ̀ si ní ilẹ̀ náà.”
Basa naa ma, ana lao hela mamanaꞌ naa, de ali seluꞌ oe mataꞌ feaꞌ fai. Ia ma, ara nda rareresi sa. Naa de Isak babꞌae oe mataꞌ naa, Rehobot, sosoa na ‘mamana loaꞌ’. Ana olaꞌ nae, “Ia naa, Lamatualain fee hita leo sia mamana loaꞌ. Sia ia dei de, hita feꞌe tamahefu naa.”
23 Láti ibẹ̀, ó kúrò lọ sí Beerṣeba.
Mia naa, Isak se lao fo reu leo sia Beer Syeba.
24 Ní òru ọjọ́ tí ó dé ibẹ̀, Olúwa sì fi ara hàn án, ó sì wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run Abrahamu baba rẹ. Má ṣe bẹ̀rù nítorí èmi wà pẹ̀lú rẹ, èmi yóò sì bùsi fún ọ, èmi yóò sì sọ iye ìran rẹ di púpọ̀, nítorí Abrahamu ìránṣẹ́ mi.”
Tetembaꞌ naa, LAMATUALAIN natudꞌu Ao na neu e, ma olaꞌ nae, “Isak! Au ia, ho ama ma Abraham Lamatualain na. Afiꞌ mumutau, te Au unea nggo. Au fee nggo papala-babꞌanggiꞌ. Ma tititi-nonosi mara boe ramahefu. Au tao taꞌo ia, huu hehelu-fufuli Ngga neu ama ma.”
25 Isaaki sì kọ́ pẹpẹ kan síbẹ̀, ó sì pe orúkọ Olúwa. Níbẹ̀ ni ó pàgọ́ rẹ̀ sí, àwọn ìránṣẹ́ rẹ sì gbẹ́ kànga kan níbẹ̀.
Basa ma Isak lutu mbatu mei tutunu-hohotuꞌ sia naa, de noꞌe makasi neu LAMATUALAIN. Ana leo sia naa, ma atahori nara ali oe fai.
26 Nígbà náà ni Abimeleki tọ̀ ọ́ wá láti Gerari, àti Ahussati, olùdámọ̀ràn rẹ̀ àti Fikoli, olórí ogun rẹ̀.
Leleꞌ naa, mane Abimelek nema mia Gerar. Ana nema no nonoo na Ahusat, ma malangga netati na, Fikol, fo randaa ro Isak.
27 Isaaki sì bi wọ́n léèrè pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin tọ̀ mí wá, níwọ̀n ìgbà tí ẹ̀yin kórìíra mi tí ẹ sì lé mi jáde kúrò lọ́dọ̀ yín?”
Isak natane nae, “Ama maneꞌ! Feꞌesaꞌan, hei oi hendi hai ena. De ia naa, hei ima mae tao saa fai?”
28 Wọ́n dáhùn pé, “A rí i dájú pé Olúwa wà pẹ̀lú rẹ, nítorí náà ni a fi rò ó wí pé, ó yẹ kí májẹ̀mú kí o wà láàrín àwa àti ìwọ. Jẹ́ kí a ṣe àdéhùn
Ara rataa rae, “Taꞌo ia! Ia naa hai bubꞌuluꞌ mae, Lamatualain nanea nggo. Huu naa, hai duꞌa-duꞌa, maloleꞌ lenaꞌ ruꞌa nggita tao hehelu-fufuliꞌ taꞌo ia: Ho sumba mae,
29 pé ìwọ kì yóò ṣe wá ní ibi, bí àwa pẹ̀lú kò ti ṣe ọ́ ní aburú, tí a sì ń ṣe ọ́ dáradára, tí a sì rán ọ jáde ní àlàáfíà láìṣe ọ́ ní ibi, kíyèsi Olúwa sì ti bùkún fún ọ.”
hei nda tao deꞌulakaꞌ mbali hai sa, onaꞌ hai o nda tao deꞌulakaꞌ mbali hei saꞌ boe. Memaꞌ hai rala mara maloleꞌ mo hei. Naa de, fai mana neuꞌ naa ra, hei lao mo mole-dame mia hai mbuku-kambo ma. Hai mihine tebꞌe-tebꞌeꞌ, LAMATUALAIN mana fee papala-babꞌanggiꞌ neu hei.”
30 Isaaki sì ṣe àsè fún wọn, wọn sì jẹ, wọ́n sì mu.
Basa ma, Isak tao fefetas, de raa-rinu raꞌabꞌue reu esa.
31 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì wọn búra fún ara wọn. Isaaki sì rán wọn lọ, wọ́n sì lọ ní àlàáfíà.
Mbila fefetu na ma, ara tao susumbaꞌ. Dei de Isak fee se baliꞌ no mole-dame.
32 Ní ọjọ́ náà gan an ni àwọn ìránṣẹ́ Isaaki wá sọ fún un pé àwọn ti kan omi ní kànga kan tí àwọn gbẹ́.
Faiꞌ naa, Isak atahori mana tao ues nara rema rafadꞌe rae oe mataꞌ fo sira aliꞌ a, hambu oeꞌ ena.”
33 Ó sì pe orúkọ kànga náà ní Ṣiba, títí di òní olónìí, orúkọ ìlú náà ni Beerṣeba.
De Isak babꞌae oe mataꞌ naa, Syeba, sosoa na ‘susumbaꞌ’. Ara babꞌae kamboꞌ naa Beer Syeba, losa faiꞌ ia.
34 Nígbà tí Esau pé ọmọ ogójì ọdún ó fẹ́ ọmọbìnrin kan tí a ń pè ní Juditi, ọmọ Beeri, ará Hiti, ó sì tún fẹ́ Basemati, ọmọ Eloni ará Hiti.
Esau too haa nulu ma, ana sao nala ana fetoꞌ rua mia leo Het. Esa, Beeri ana na, naran Yudit. Ma esa fai, Elon ana na, naran Basmat.
35 Fífẹ́ tí a fẹ́ àwọn obìnrin wọ̀nyí jẹ́ ìbànújẹ́ fún Isaaki àti Rebeka.
Inaꞌ ka ruaꞌ naa ra, raꞌasususaꞌ Isak no Ribka rala nara.

< Genesis 26 >